Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Aarẹ Muhammadu Buhari ti yan igbakeji ọga ọlọpaa tẹlẹ, Alkali Usman Baba,…
Author: admin
Makinde ṣeleri iranwọ fawọn oniṣowo ti ina ba dukia wọn jẹ n’lsọ paati n’Ibadan
Ọlawale Ajao, Ibadan Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ẹnjinnia Ṣeyi Makinde, ti ṣeleri iranlọwọ fawọn ontaja ti…
Nitori ọrọ aabo, Sheikh Gumi ṣabẹwo s’Ọbasanjọ l’Abẹokuta
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Gbajugbaja Aafaa ilu Kaduna nni, Sheikh Ahmad Gumi, ti ṣabẹwo si aarẹ…
Aburo iyawo ẹ ni Jonas ki mọlẹ, lo ba ṣe e yankanyankan ni Festac
Faith Adebọla, Eko Jonas Nnubia ni wọn porukọ baale ile ẹni ọdun mẹrinlelogoji yii,…
Òkèlè nla to nira lati gbe mi ni iku Yinka Odumakin – Ọọni
Florence Babaṣọla Arole Oduduwa to tun jẹ Ọọni ti Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja…
Gani Adams ni ki wọn gbe kọmiṣanna ọlọpaa Ọyọ kuro, o lobìnrin naa ko jafafa to
Ki eto aabo le fẹsẹ rinlẹ daadaaa nipinlẹ Ọyọ, Aarẹ Ọnakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani…
Apaayan ọmọ ẹgbẹ ‘Ẹiyẹ’ ni Ṣẹgun, ibi to ti n sa kiri lọwọ ti ba a n’Ikorodu Faith Adebọla, Eko
Faith Adebọla, Eko Ti wọn ba n wa oṣikatan tẹsẹ mọrin ẹda, ọkunrin…
Oṣiṣẹ banki kowo awọn onibaara jẹ l’Abẹokuta, nile-ẹjọ ba sọ ọ sẹwọn oṣu kan aabọ
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Oṣiṣẹ banki kereje (Micro finance) ni Ọgbẹni Philips Ogorome, ẹni ọdun mọkanlelogoji…
A fura pe Yinka yoo ku – Jacob Odumakin
Ọkan lara awọn ẹgbọn Oloogbe Yinka Odumakin, Pasitọ Jacob Odumakin, ti sọ pe asọtẹlẹ ti…
Eyi ni bawọn Fulani ṣe tun ya wọnu oko oloko n’Ibadan, eeyan mẹta ni wọn ji gbe
Ọlawale Ajao, Ibadan O kere tan, eeyan mẹta lawọn Fulani ajinigbe tun ji gbe n’Ibadan…
Adigunjale ni Saidi, ibọn ibilẹ lo fi n da wọn laamu ni Festac
Faith Adebọla, Eko Saidi Adewale lorukọ ọmọ ọdun mẹtadinlogoji yii, ọdọ awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ…