Ọlawale Ajao, Ibadan Igbimọ ti ijọba ipinlẹ Ọyọ gbe kalẹ lati ṣewadii iya to jẹ…
Author: admin
Ẹwọn n run nimu Raji, ọmọ ọdun mẹtala lo fun loyun ni Saki
Afaimọ ki ọkunrin ẹni ọdun mọkandinlaaadọta kan, Tairu Raheem, ma faṣọ penpe roko ọba lori ẹsun…
Afẹnifẹre gboṣuba nla fawọn OPC ti wọn mu Wakili Isikilu to n da awọn eeyan laamu n’Ibarapa
Ẹgbẹ Afẹnifẹre ti fidimule wọn han si bi ọwọ ṣe tẹ ọga awọn Fulani, Isikilu Wakilu,…
Ada yanran-yanran ni wọn ba lọwọ Joshua atawọn ọrẹ ẹ ti wọn jọ n ṣẹgbẹ okunkun l’Ekoo
Faith Adebọla, Eko Akolo awọn ọlọpaa ọtẹmuyẹ to wa ni Panti,…
Ọpẹ o, wọn ti ri awọn arinrinajo tawọn ajinigbe ji gbe loju-ọna Oṣogbo si Ibokun
Florence Babaṣọla Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọṣun ti kede pe eeyan meje tawọn ajinigbe ji lalẹ…
Ọwọ ẹsọ Amọtẹkun tẹ awọn ọkunrin meji ti wọn n ṣe ‘kinni’ funra wọn l’Akurẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Boroboro bii ajẹ to jẹ eepo ọbọ ni awọn ọkunrin…
Ibi ti Ambọde n tukọ ipinlẹ Eko lọ ko dara la ko ṣe ṣatilẹyin fun saa keji rẹ – Tinubu
Faith Adebọla, Eko Aṣaaju apapọ fẹgbẹ oṣelu All People’s Congress, APC, to tun…
Aisun ọdun tuntun lemi ati baba mi ti n bọ tawọn ọlọpaa fi yinbọn pa wọn n’Iwoo – Oluṣẹgun
Florence Babaṣọla Oluṣẹgun Ọlaoṣebikan fara han niwaju igbimọ tijọba ipinlẹ Ọṣun gbe kalẹ…
Akeredolu pasẹ pe kawọn ileewe maa kọrin ibilẹ Yoruba
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Gomina Rotimi Akeredolu ti ni o di dandan fun gbogbo…
Awọn ọmọ ẹgbẹ PDP fẹhonu han l’ Ọyọọ, wọn ni wọn fi tipa yan oludije le awọn lori
Ọlawale Ajao, Ibadan O fi han pe nnkan ko lọ deede ninu ẹgbẹ oṣelu…
Awọn agbebọn pa Samson l’Akungba Akoko, wọn tun ji ọkada rẹ lọ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ. Awọn ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ iku ọlọkada kan, Samson Owodayọ,…