Ayọdeji ati ọrẹ ẹ ti jẹwọ: Loootọ ni, awa la pa Tolulọpẹ, akẹkọọ Fasiti FUOYE

Boya ni Ayodeji ati Ọrẹ yii koni ṣewọn o, Ọmọ Yunifasiti FUOYE ni wọn pa Taofeek…

Mi o sọ pe kẹ ẹ dibo fun Buhari ni 2015 o, Jonathan ni mo ni kẹ ẹ le lọ -Ṣoyinka

Faith Adebọla, Eko Ogbontarigi akọwe-kọ-wura nni, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka, ti bẹnu atẹ lu awọn ti wọn…

Wọn ti jawe oye le Ogunṣua Mọdakẹkẹ tuntun lori

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Lẹyin oṣu kan ti Ogunṣua ilu Mọdakẹkẹ tẹlẹ, Ọba Moses Ọladẹjọ Oyediran, Ajombadi…

Toogun si ge Mọdinat si wẹwẹ bii ẹran ewurẹ, oogun owo lo fẹẹ fi i ṣe n’Ileogbo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọkunrin afurasi apaniṣowo kan, Toogun, ti wa lakolo ọlọpaa ipinlẹ Ọṣun bayii lori…

James atọrẹ ẹ yin Adefisayọ lọrun pa lẹyin ti wọn fipa ba a lo pọ tan l’Ogijo

Gbenga Amos, Abẹokuta Ọmọkunrin ẹni ọdun mẹrinlelogun kan, James Ikenna ati ọrẹ ẹ kan to ṣi…

Ọlọpaa yii wọ gau, owo ẹyin lo gba lọwọ agunbanirọ l’Ekoo

Faith Adebọla, Eko Ọga ọlọpaa lọkunrin yii, ASP Joseph Eyitere to n ṣiṣẹ ni ẹka ileeṣẹ…

Mo ti ṣetan lati gba isakoso ipinlẹ Ọṣun lọwọ Oyetọla – Lasun Yusuf

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Igbakeji olori ileegbimọ aṣoju-ṣofin lorileede yii tẹlẹ, Ọnarebu Lasun Yusuf, ti fi ọwọ…

Arun Iba Lassa ṣeku pa alaboyun kan l’Ọṣun

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oludamọran pataki fun gomina ipinlẹ Ọṣun lori ọrọ ilera, Dokita Ọlaṣiji Ọlamiju, ti…

Ọmọbinrin yii maa n dibọn bii ẹni to fẹẹ ran awọn ti ko mọ kaadi ATM i lo lọwọ, ni yoo ba paarọ ẹ mọ wọn lọwọ

Faith Adebọla Oriṣiiriṣii kaadi ATM ti wọn fi n gbowo lẹnu ẹrọ mẹtadinlogun ni wọn ba…

Ẹni keji la n ja lole lọwọ tawọn ọlọpaa fi mu wa – Aro Ghetto Boy

Faith Adebọla, Eko Ori gige ika abamọ jẹ lọwọ lawọn gende mẹta yii wa lọwọlọwọ yii,…

Ijọba fofin de ẹgbẹ onimọto, wọn sọ MC Oluọmọ di alaga igbimọ gareeji l’Ekoo

Faith Adebọla, Eko Ijọba ipinlẹ Eko ti kede iyansipo Alaaji Musiliu Ayinde Akinsanya tawọn eeyan mọ…