Eeyan mẹta ku, ọpọ fara pa, lasiko tawọn tọọgi kọju ija sira wọn l’Ọffa

Ibrahim Alagunmu O kere tan, eeyan mẹta lo ti rọrun alakeji, nigba ti ọpọlọpọ fara pa…

Wọn ba ori ati ọwọ eeyan lọwọ Ibrahim ati Wasiu ni Kwara, oogun owo ni wọn fẹẹ fi i ṣe

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Akolo ọlọpaa lawọn ọkunrin meji yii, Wasiu Omonose, ẹni ọdun marundinlogoji, ati ẹnikeji…

Ijọba ipinlẹ Eko ṣi ileewe Chrisland pada

Monisola Saka Ijọba ipinlẹ Eko, latọwọ ileeṣẹ to n ri si eto ẹkọ n’ipinlẹ Eko, ti…

Adanu nla ni iku Alaafin jẹ fun iran Yoruba – Oluwoo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oluwoo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, ti ṣapejuwe iku Alaafin ti…

Ori ko awọn arinrin-ajo mẹsan-an yọ lọwọ awọn ajinigbe l’Ọrẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn arinrin-ajo bii mẹsan-an lori ko yọ lọwọ awọn ajinigbe loju ọna marosẹ…

Ẹ wo Samuel atawọn ikọ rẹ ti wọn n digunjale l’Ọwọ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti fi pampẹ ofin gbe awọn ikọ adigunjale ẹlẹni mẹta…

Nitori isinku Alaafin, isede wa niluu Ọyọ lati aago mẹjọ alẹ

Ọlawale Ajao, Ibadan Lati ṣe gbogbo etutu to yẹ lori iku ọba nla to waja nilẹ…

Aago mẹrin irọlẹ ni Ọba Adeyẹmi yoo wọ kaa ilẹ lọ

Ọlawale Ajao, Ibadan Aago mẹrin, nirọlẹ ọjọ Abamẹta, Satide yii, ni wọn yoo sinku Ọba Adeyẹmi…

Kayeefi nla, Owolabi ni ile aye su oun, lo ba fẹẹ pokunso ni Kwara

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ọjọ Ẹti, Furaide, opin ọsẹ to lọ yii, ni Arakunrin kan, Ọlayinka Ṣẹgun…

Erin wo! Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi, ti waja

Ọlawale Ajao, Ibadan Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi, ti darapọ mọ awọn baba nla rẹ…

Aisha Buhari fiwe pe awọn oludije dupo aarẹ, o ni ki wọn ma mu foonu wọn dani wa

Mosunmọla Saka Gbogbo awọn oludije dupo aarẹ kaakiri awọn ẹgbẹ oṣelu nilẹ Naijiria ni wọn yoo…