Ọlawale Ajao, Faith Adebọla Aṣigangan tilu Igangan, Ọba Abdul-Azeez Adeoye Adewuyi, Aribiyan keji, Gbadewọlu ki-in-ni, ti…
Category: Ìròyìn
Diẹ lo ku ki wọn dana sun mi lori ọrọ ti mi o mọ nnkan kan nipa ẹ n’Ibadan-Tọpẹ Aluko
Ọlawale Ajao, Ibadan Aṣe loootọ lowe awọn agba to sọ pe ori yeye ni mogun, taiṣẹ…
Mo ti dariji gbogbo awọn to fiya jẹ mi lai ṣẹ-Wolii Ṣọtitọbirẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ara ọtọ patapata ni isin ọjọ isinmi to kọja yii jẹ fawọn ọmọ…
Eyi lohun to fa a ti mo fi ni ibanujẹ ọkan-Ibrahim Chatta
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Latigba ti Ibrahim Chatta, gbajumọ oṣere tiata ti ni inu oun ko dun,…
Wọn lawọn obi yoo maa tọwọ bọwe adehun alaafia lori awọn akekọọ girama l’Ogun
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Nitori awọn iwa janduku ati jagidijagan tawọn akẹkọọ ileewe girama kan n hu…
FRSC kilọ fawọn awakọ nitori abala ti wọn ṣi ni Lotto si Deeper Life
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Nitori ki sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ma baa pọ ju lasiko ọdun Keresimesi loju ọna…
Afi ki Buhari tete gbe igbesẹ lati da orileede yii pada ni bebe iṣubu to wa ko too pẹ ju-Ortom
Faith Adebọla Ọjọ pataki ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kejila, jẹ nigbesi aye olori orileede wa, Ajagun-fẹyinti…
Ogun eeyan tun kagbako iku ojiji ni Kaduna, wọn dana sun mọto ati ounjẹ wọn
Faith Adebọla O kere tan, ogun lara awọn eeyan to dagbere p’awọn n lọọ sun lalẹ…
Tọkọ-tiyawo ta ọmọ oṣu kan lẹgbẹrun lọna aadọta naira l’Ode-Rẹmọ
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Tọkọ-taya lawọn eeyan meji yii, orukọ ọkọ ni Eze Onyebuchi, iyawo ni Oluchi…
Fayawọ epo lawọn mẹta yii fẹẹ ṣe wọ ilẹ Bẹnin tọwọ fi tẹ wọn ni Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ọjọ Ẹti, Furaidee, ọṣẹ to kọja yii, lọwọ ajọ ẹsọ alaabo ṣifu difẹnsi,…
Mo ni arun ibanujẹ ọkan, mo kan n dibọn bii pe ko si nnkan ni- Ibrahim Chatta
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bi ko ba si aṣọ to n b’aṣiri idi, oniruuru idi la ba…