Awọn ọlọpaa ba mu Ọba Tẹjuoṣo, wọn lo lu obinrin to fẹẹ fẹ ni jibiti

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Adabọnyin Ẹkun, Ọba Adetokunbọ Gbadegẹṣin Tẹjuoṣo, Olu Orile Kemta, l’Abẹokuta, to sọrọ soke…

Eyi lawọn ohun to n fa wahala lawọn ile-ẹkọ yunifasiti wa

Ni orilẹ-ede Naijiria tiwa loni-in yii, o fẹrẹ ma si ọdun kan ti awọn olukọ yunifasiti…

O ma ṣe o! Akẹkọọ Fasiti LAUTECH ja sinu sọkawee, lo ba ku patapata

Ọlawale Ajao, Ibadan Waiwai ni inu ọgba Ladoke Akintọla University of Technology (LAUTECH), to wa niluu…

Wọn tun ji Abraham gbe l’Ayetẹ

Ọlawale Ajao, Ibadan Ọrọ awọn arinrianjo ti wọn ji gbe lọna Eruwa la ṣi n sọ…

Ọkada lawọn eleyii lọọ ji gbe tọwọ fi tẹ wọn ni Kwara

Stephen Ajagbe, Ilorin Afurasi mẹta; Abdullahi Yaro, Abdulganiu Muhammed ati Baki Adamu, ni wọn ti ko…

Awọn janduku dana sun ile gomina ipinlẹ Imo, wọn tun pa ẹṣọ meji

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Laaarọ ọjọ Abamẹta, Satide, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹrin yii, ni awọn janduku kan…

Ẹ kilọ fun Fayẹmi ko ma ta ilẹ wa fawọn Fulani o-PDP Ekiti 

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Ẹgbẹ People’s Democratic Party (PDP) ipinlẹ Ekiti ti fẹsun kan Gomina Kayọde Fayẹmi…

Ọlọpaa ti ri Alaga ti wọn ji gbe l’Oke-Onigbin, nipinlẹ Kwara, gba pada

Stephen Ajagbe, Ilorin Ọga ọlọpaa ni Kwara, Mohammed Lawal Bagega, ti kede pe awọn doola oniṣowo…

Awọn agbebọn ji alakooso kansu l’Ekiti

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Awọn agbebọn ti ji alakooso fun eto ọgbin nijọba ibilẹ Iwọ-Oorun Ekiti, Ebenezer…

Ti mo ba tun aye wa, Yinka ni ma a fẹ – Joe Odumakin

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Iyawo Oloogbe Yinka Odumakin, Joe, ti sọ pe to ba ṣee ṣe fun…

Ara Kẹmi Afọlabi, oṣere tiata, ko ya o

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Kẹmi Afọlabi Adeṣipẹ, ọkan lara awọn oṣerebinrin nilẹ yii, ti jẹ ko di…