Ẹ woju wọn, awọn ni wọn pa Barakat, ti wọn tun pa alaboyun atawọn mi-in l’Akinyẹle, n’Ibadan

  Titi di ba a ṣe n sọ yii ni gbogbo awọn to wa nibi tawọn…

Ipade alaafia awọn oludije sipo gomina ẹgbẹ APC Ondo fori sanpọn

  Iyiade Oluṣẹyẹ, Akurẹ Afaimọ ki fa-a-ka-ja-a to n fojoojumọ ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ…

Nitori bi korona ṣe pa ọkan ninu wọn, awọn aṣofin Eko bẹrẹ ayẹwo

  Latari aṣẹ tileegbimọ aṣofin Eko  pa pa pe ki gbogbo awọn ọmọ ile aṣofin naa,…

N’ILE-IFẸ, WỌN NI JUBIRILA J’IYAWO ONIYAWO GBE TỌMỌTỌMỌ

Wọn ti wọ ọkunrin kan to n jẹ Jubril Anifowoṣe lọ sile-ẹjọ ni Ile-Ifẹ o. Lanaa…

Ẹgbọn Tolulọpẹ ti sọrọ o, o ni iku aburo oun ki i ṣoju lasan

Oriṣiiriṣii awuyewuye lo ti n lọ lori iku to pa ọdọmọbinrin kan, Tolulọpẹ Arotile, ẹni to…

Wọn ti yan Yaya Bello gẹgẹ bii alaga igbimọ ti yoo ṣeto idibo abẹle APC nipinlẹ Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ  Gomina ipinlẹ Kogi, Alaaji Yaya Bello, ni wọn ti kede orukọ rẹ gẹgẹ…

Ẹgbẹ APC kede orukọ awọn oludije to kunju oṣuwọn lati kopa ninu ibo abẹle l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ẹgbẹ oṣelu APC yii ti kede orukọ awọn to kunju oṣuwọn ati kopa…

Awọn ileewe ilẹ Yoruba yoo ṣi loṣu to n bọ

Oluyinka Soyemi Awọn ileewe to wa lawọn ipinlẹ mẹfẹẹfa nilẹ Yoruba yoo ṣi lọjọ kẹta, oṣu…

Magu kuro lahaamọ lẹyin ọjọ kẹwaa

Alaga ajọ to n gbogun ti ṣiṣe owo ilu basubaṣu tẹlẹ, Ibrahim Magu, ti kuro ninu…

Awọn alaga kansu ipinlẹ Ọyọ to pe Makinde lẹjọ fidi-rẹmi ni kootu

Ọlawale Ajao, Ibadan Lẹyin ti Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ẹnjinnia Ṣeyi Makinde, ti fi aṣẹ ijọba le…

Awọn eeyan ṣedaro Arotile, obinrin akọkọ to jagun pẹlu baaluu agberapa

Oluyinka Soyemi Lati ana, ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ti iroyin iku Tolulọpẹ Arotile ti gba igboro kan…