Ijọba yoo ṣi awọn ileejọsin loṣu to n bọ nipinlẹ Ogun– Dapọ Abiọdun

Adefunkẹ Adebiyi, Ogun Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ yii, ni Gomina ipinlẹ Ogun, Omọọba Dapọ Abiọdun, kede lọfiisi…

Godwin fipa ba abirun lo pọ ni Sango, lo ba loun ti ṣe e tan koun too mọ pe ko daa

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta  Ọmọbinrin kan ti ara rẹ ko da pe pade agbako ibasun lanaa ode…

O ma ṣe o,  awọn janduku pa eeyan mẹtala ninu mọlẹbi kan naa ni Kogi

 Eeyan mẹrinla lawọn janduku kan pa loru Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ yii, nipinlẹ Kogi, nigba ti awọn…

Eyi le o, lọjọ kan ṣoṣo, Korona paayan mẹta l’Ọyọọ

Ọlawale Ajao, Ibadan Gende Ọlọrun mẹta lajakalẹ arun Korona pa lọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọsẹ yii. O…

Ayedatiwa ni yoo ṣe igbakeji Gomina Akeredolu ninu eto idibo ti yoo waye loṣu kẹwaa

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu  ti forukọ ẹni to fẹẹ fi ṣe igbakeji…

Oku rẹpẹtẹ ni Kaduna: Awọn Fulani onimaalu fẹẹ dogun silẹ ni o

Ihooho ni pupọ ninu wọn jade, paapaa awọn ti wọn jẹ agbalagba ninu wọn. Awọn obinrin…

Haa, obinrin yii si n gba iṣo mọ ọmọ ọkọ ẹ kekere yii lori

Awọn ọlọpaa Ṣagamu ti mu un o. Abimbọla. Koda wọn tun mu ọkọ ẹ naa, Taiwo…

Pasito Kumuyi, olori ijọ Deeper Life, kọ Bibeli tuntun

Olori ati Oludasilẹ ijọ awọn Dipa (Deeper Life) Pasitọ William Kumuyi, ti kọ Bibeli tuntun ni…

Awọn eleyii fipa ba obinrin sun l’Ogijo, wọn tun fidio rẹ

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ṣọla Ọlaoluwa, Ibrahim Kẹhinde ati Lukman Banjoko lẹ n wo yii, awọn pẹlu…

Dokita Amẹrika ti ni ki wọn ma sọ pe ko soogun fun korona mọ, oogun ẹ wa o jare

Obinrin oniṣegun oyinbo kan ni orilẹ-ede Amerika, Dokita Stella Emmanuel, ti sọ pe oogun wa fun…

‘Tori pe a ko rẹni ya wa lowo lati ṣowo to wu wa la fi bẹrẹ si i digunjale’

Faith Adebọla, Eko Awọn adigunjale meji yii, Sule Abdulkareem, ẹni ọdun mọkandinlọgbọn, pẹlu ekeji ẹ, Celestine…