Koronafairọọsi: Ofin konilegbele n palẹmọ diẹdiẹ l’Ekiti

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Lalẹ ọjọ Iṣẹgun, Tusidee to kọja, ni Gomina Kayọde Fayẹmi tipinlẹ Ekiti kede…

Ọrọ yii ṣi maa dija: Wọn ti gba APC lọwọ Tinubu o

Nigba ti alaga igbimọ awọn gomina ẹgbẹ APC, Atiku Bagudu to tun jẹ gomina ipinlẹ Kebbi…

Olori oṣiṣẹ Gomina Zulum tipinlẹ Borno jade laye

Olori oṣiṣẹ Gomina Babagana Zulum tipinlẹ Borno, Babagana Wakil, ti jade laye. Wakil lo jẹ Ọlọrun…

Ijọba apapọ fi kun owo-epo bẹntiroolu

Ijọba apapọ ilẹ Naijiria ti fi kun owo epo bẹntiroolu, eyi to gbera kuro ni naira…

Awọn ẹruuku tun ya wọ Akinyẹle, n’Ibadan, wọn ṣa iya atọmọ ladaa

Ọlawale Ajao, Ibadan Pẹlu bi awọn ẹni ibi kan ṣe n pa awọn eyan nipakupa lagbegbe Akinyẹle, n’Ibadan, awọn…

Ọwọ tẹ Tọpẹ nibi to ti n fọle onile l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Diẹ lo ku ki wọn dana sun afurasi adigunjale kan, Tọpẹ Owolabi, tọwọ…

Micheal ti wọn sọ pe o payawo atọmọ ẹ n’Ileefẹ ti foju bale-ẹjọ

Michael Adunọla ti fara han niwaju ile-ẹjọ Majisreeti ilu Ileefẹ lori ẹsun pe o pa iyawo…

Ile-ẹjọ sọ awọn ọmọ orileede India meji to n ji epo rọbi satimọle

Faith Adebọla, Eko Afaimọ kawọn ọmọ ilẹ India meji yii, Akash Kumar ati Vishal Guleria ma…

IDAAMU OLUWOO: Ọba to ti ṣẹwọn l’Amẹrika nigba kan

Loootọ ni Ọba naa ti n jagun tipẹ, bo tilẹ jẹ pe ọpọ ogun naa jẹ…

Sunday ọlọkada gbe ọmọ ẹgbẹ okunkun pẹlu ibọn n’Ijẹbu-Ode, ni wọn ba ko sọwọ ọlọpaa

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bo tilẹ jẹ pe Sunday Francis, ọlọkada ẹni ọdun mejidinlogoji (38) n’Ijẹbu-Ode, sọ…

Oogun oloro: Ajọ NDLEA ṣekilọ fawọn ọdaran lẹyin tọwọ tẹ mọkandinlaaadọfa

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Adari ajọ to n gbogun ti oogun oloro nilẹ yii (NDLEA), ẹka tipinlẹ…