Azeez Agboọla lorukọ ọkunrin ti ẹ n wo yii, ẹni aadọta ọdun (50 years) ni. Iṣẹ…
Ọkada ko sabẹ tirela, lo ba tẹ ọmọ iya kan naa meji pa ni marose Ṣagamu
Adefunkẹ Adebiyi,Abẹokuta Ai le ni suuru ati wiwa ọkada niwakuwa loju ọna marosẹ lo da ẹmi…
Ogun lakaaye la maa bẹ lọwẹ si ẹṣọ Amọtẹkun to ba huwa to ta ko idasilẹ rẹ-Wọle Ṣoyinka
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ikọ ẹṣọ alaabo ilẹ Yoruba nni, Amọtẹkun, ti ṣetan lati bẹrẹ iṣẹ lakọ…
Inu oko ti Amaka ti n ṣiṣẹ lawọn Fulani ka a mọ, wọn si ṣa a ladaa yannayanna
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Obinrin kan, Amaka Okafor, lawọn Fulani tun lọọ ba ninu oko rẹ niluu…
Ọwọ ọlọpaa tẹ awọn afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun mẹrindinlogun n’Ilọrin
Stephen Ajagbe, Ilorin Awọn afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun Aiye ati Ẹiyẹ mẹrindinlogun lọwọ ọlọpaa tẹ lagbegbe…
Lawal luyawo ẹ pa, o lẹkọ mimu to po foun di koko
Ẹka ti wọn ti n gbọ ẹjọ awọn apaayan ni ọkunrin yii, Danladi Lawal, ẹni ogun…
Ileepo ti wọn ni ki Abiọdun maa sọ loun atawọn ọrẹ ẹ lọọ ja lole l’Ondo
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn agba bọ, wọn ni bi iku ile ko ba pa ni, tode…
Ọkọ pẹlu ale n ja soyun Maryam n’Ibadan
Ọlawale Ajao, Ibadan “Oniṣina paraku niyawo mi. O tun maa n ṣe ṣina pẹlu oyun ninu.…
Ọwọ tẹ Monday, ọmọ ogun ọdun to fipa ṣe ‘kinni’ fun’ya arugbo n’Ifọn
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọwọ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti tẹ Monday Asaba lori ẹsun fifi ipa…
Awọn to n gba Buhari nimọran lo n ṣi i lọna- Lawan
Faith Adebọla Olori awọn aṣofin ilẹ wa, Sẹnetọ Ahmed Lawan, ti koro oju si bawọn eeyan…
Wọn ti yọ alaga kansu Onigbongbo bii ẹni yọ jiga, wọn lo kowo jẹ
Faith Adebọla, Eko Awọn kansẹlọ ijọba ibilẹ Onidagbasoke Onigbogbo, nipinlẹ Eko, ti fọwọ osi juwe ile…