Ibo abẹle Ondo:Ajayi ki Jẹgẹdẹ ku oriire, o loun tí gba f’Ọlọrun

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ  Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Ọnarebu Agboọla Ajayi, ti ki Eyitayọ Jẹgẹdẹ ku oriire…

IBO AWỌN PDP L’ONDO: JẸGẸDẸ WỌLE, AGBOỌLA JA BỌ!

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Pẹlu gbogbo ilakaka Igbakeji Gomina Ipinlẹ Ondo, Ajayi Agboọla, lati koju  ọga rẹ,…

Nitori Korona, Awujalẹ fagi le Ojude Ọba t’ọdun yii

Nitori arun aṣekupani Koronafairọọsi to gbode kan, Awujalẹ ilẹ Ijẹbu, Ọba Sikiru Adetọna ti kede pe…

Wọn tun ti ji awọn arinrin-ajo meji gbe l’Akoko

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Iṣẹlẹ ijinigbe to n waye lagbegbe Akoko tun gbọna mi-in yọ pẹlu bi…

Gomina Abdulrazaq ṣabẹwo sileeṣẹ tẹlifiṣan NTA Ilọrin to jona

Stephen Ajagbe, Ilọrin Lalẹ ana, ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ni Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrazaq Abdulrahman, ṣabẹwo sileeṣẹ tẹlifiṣan tijọba apapọ, NTA,…

Ẹni tọwọ ba tẹ pe ko lo ibomu atawọn to gba wọn laaye yoo foju bale-ẹjọ ni Kwara

Stephen Ajagbe, Ilọrin Nitori bi atankalẹ arun Koronafairọọsi ṣe n fojoojumọ gbilẹ nipinlẹ Kwara, ijọba ti…

Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi ti ko arun Koronafairọọsi o

Gomina Kayọde Fayẹmi tipinlẹ Ekiti ti ko arun Koronafairọọsi. Gomina ọhun funra ẹ lo ṣe ikede…

O ma wa ga o, wọn tun pa ọmọ ọdun mẹrindinlogun mi-in l’Akinyẹle, n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Niṣe ni gbogbo eeyan ro pe iku ojiji tawọn olubi ẹda kan fi…

Ija de: Alaafin lo nilẹ ni, abi awọn ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi?

Ni bayii, o da bii pe ẹgbẹ awọn Kristẹni ti wọn n pe ni CAN (Christian…

O ma ṣe o, terela Dangote tun pa baba atọmọ ẹ ni Lọkọja

Ọrọ terela Dangote to paayan ni ipinẹ Ogun ni lọsẹ to kọja lawọn eeyan ṣii n…

Buhari yari, o ni, ‘E ma ba mi le awọn eeyan mi lọ!’

Aarẹ orilẹ-ede yiii, Ọgagun agba Muhammadu Buhari ti yari mọ awọn aṣofin Naijiria lọwọ bayii o,…