Ọmọlayọ ti dero ẹwọn, tiṣa loun atawọn ẹgbẹ ẹ lu lalubami

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ile-ẹjọ Majisireeti to fikalẹ siluu Odigbo, ti ni ki akẹkọọ kan ti ko…

Nitori ẹjọ ti adajọ da fun un, Akala fo windo jade ni kootu, lo ba fere ge e

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ṣe lọrọ ọhun da bii ere ori-itage, nigba ti ọkunrin afurasi kan ti…

Ẹgbẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ mọnamọna lawọn yoo darapọ mọ NLC fun iyanṣẹlodi ti wọn fẹẹ ṣe

Monisọla Saka Awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ mọnamọna jake-jado orilẹ-ede Naijiria, labẹ ẹgbẹ wọn ti wọn n pe…

Ẹgbẹ onimọto Ọyọ: Makinde yan Ọmọlẹwa, Tokyo, Ejiogbe rọpo Auxiliary

Ọlawale Ajao, Ibadan Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ẹnjinnia Ṣeyi Makinde, ti yan awọn eeyan tuntun sinu igbimọ…

Adajọ ni ki wọn lọọ yẹgi fawọn obinrin mẹta ti wọn jẹbi ẹsun ijinigbe

Faith Adebọla  Boya owe awọn agba ti wọn ni ọdẹ ki i pa ọdẹ jaye, ko…

Ile-ẹjọ maa gba ẹtọ mi pada fun mi lọwọ ijọba awuruju yii-Atiku

Adewale Adeoye Ondije dupo aarẹ orileede yii lẹgbẹ oṣelu ẹgbẹ PDP ninu ibo aarẹ to waye…

Dukia Buhari ko le si i fodidi ọdun mẹjọ to fi ṣejọba -Garba Sheu

Adewale Adeoye ‘‘Fun odidi ọdun mẹjọ gbako ti olori orileede yii tẹlẹ, Ajagun-fẹyinti, Muhammadu Buhari, fi…

Aarẹ Tinubu gbọdọ da owo epo bẹntiroolu pada si bo ti ṣe wa tẹlẹ-TUC

Adewale Adeoye Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ kan ti wọn n pe ni ‘ Trade Union Congress’…

Owo iranwọ epo: Eyi nidi ta a ṣe fẹẹ dasẹ silẹ-Ẹgbẹ oṣiṣẹ

Monisọla Saka Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹ-ede Naijiria, Nigerian Labour Congress, (NLC), ti fi atẹjade sita lori…

Diẹ lo ku ki wọn fi lilu ran Isiaka sọrun, ewure lo ji gbe n’Ilọrin

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ẹṣinburuku ni wọn fi ogbologboo ole kan, Isiaka, to ji ewurẹ gbe niluu…

Eyi lohun to ṣẹlẹ si ọmọ Alabi Pasuma l’Amẹrika

Faith Adebọla Ọmọ to ba mowo dele lobi rẹ yoo yin, gbogbo obi si ni wọn…