Nitori b’awọn Fulani ṣe tun paayan meji l’Owode-Ketu, awọn eeyan sa kuro niluu

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹ́òkúta Ni fẹẹrẹ Ọjọbọ, ọjọ kọkanla, oṣu keji yii, lawọn Fulani ti awọn ara…

Lẹyin tawọn Fulani pa agbe kan tan ni wọn tun dana sun oko koko rẹ n’Igangan

Ọlawale Ajao, Ibadan Awọn amòòkùṣìkà Fulani darandaran tun ti sọ̀kò ìbànújẹ sí agbagbe Ibarapa lẹẹkan sí…

Awọn to fẹẹ gba gareeji lo fa ijaagboro to ṣẹlẹ l’Ọbalende-Jimoh

Faith Adebọla, Eko Inu idarudapọ lawọn eeyan agbegbe Ọbalende ji si laaarọ kutu Ọjọbọ, Tọsidee yii,…

Ijọba ko ni i faaye gba ẹnikẹni lati ṣe iwọde kankan ni Too-Geeti Lẹkki-Lai Muhammed

Minisita fun eto iroyin nilẹ wa, Alaaji Lai Muhammed, ti sọ pe ijọba ko ni i…

Gomina ipinlẹ Eko tele, Lateef Jakande, ti ku o

Alhaji Lateef Jakande, gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, ti jade laye lẹni ọdún mọkanlelaaadọrun-ùn.Owurọ kutu Ọjọbọ, Tọsidee,…

Ọwọ ti tẹ Tina, ọmọ lanledi to lu tẹnanti wọn pa tori owo ina n’Ikorodu

Faith Adebọla, Eko Ahamọ ọlọpaa ni ọmọbinrin kan, Tina Essi, wa bayii latari bi wọn ṣe…

Ọlọpaa ti mu awọn Fulani to pa Alaaja Sherifat, ọga ileepo l’Ayetẹ

Ọlawale Ajao, Ibadan O kere tan, ọwọ awọn agbofinro ti tẹ marundinlogoji (35) ninu awọn afurasi…

Lasiko tawọn to ji mi gbe sun lọ fọnfọn ni mo sa mọ wọn lọwọ loruganjọ- Atẹrẹ

Stephen Ajagbe, Ilorin Baale ile ẹni ọdun mẹrindinlaaadọta, Alhaji Musa Garba Atẹrẹ, tawọn ajinigbe ji gbe…

Ẹwọn n run nimu Yusuf o, ọmọ bibi inu ẹ lo binu ju sodo ni Badagry

Faith Adebọla, Eko Eebu ati epe loriṣiiriṣii lawọn eeyan n ṣẹ le baba ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn…

Ọwọ tẹ ọkọ to fẹẹ ba’yawo rẹ ṣedanwo igbaniwọle awọn olukọ l’Ọṣun

Florence Babaṣọla Ọwọ awọn ikọ Sifu Difẹnsi ti tẹ ọkunrin kan, Adekunle Arẹmu, lori ẹsun pe…

O maa n wu mi bawọn ẹgbẹ mi ṣe n sọ, ati ka ede oyinbo, lo jẹ ki n pada sileewe – Fọlaṣade

Stephen Ajagbe, Ilorin Iyaale ile ẹni ọdun mejidinlogoji kan, Ajayi Fọlaṣade, to wa ni kilaasi JSS2,…