Gbenga Amos, Ogun “Ẹ jẹ ki n lo anfaani yii lati sọ fawọn eeyan wa pe…
Author: omotanbaje
Dandan ni ki APC bori ibo 2023, a o fẹẹ pẹjọ rara – Adamu
Faith Adebọla Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Sẹnetọ Abdullahi Adamu, ti sọ pe dandan…
Ọdẹ adugbo yinbọn pa mẹkaniiki, wọn tun ji owo ẹ lọ l’Oṣogbo
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọmọkunrin atọkọṣe kan, Mohammed Badmus, ẹni ogoji ọdun, ni ọdẹ adugbo Ibuowo Estate,…
Nitori Ọbabinrin Elizabeth, awọn aye n bu Tọpẹ Alabi
Faith Adebọla, Eko Titi dasiko yii ni oriṣiiriṣii ọrọ idaro, ibanikẹdun ati oriyin n rọjọ nilẹ…
Idi ti mo fi lu baba mi pa niyi-Hassan
Ibrahim Alagunmu Akolo ọlọpaa ipinlẹ Kwara, ni gende ẹni ọdun mejilelọgbọn kan, Ibrahim Hassan, wa bayii, latari…
Ẹya Yoruba la n ba lọ, ẹ fun wa lẹtọọ wa – Ẹgbẹ Yoruba parapọ Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin L’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii, ni ẹgbẹ Yoruba parapọ ni Kwara, rọ ijọba apapọ…
Awọn ọmọ Hausa yii lọọ ji waya ina tu n’Ikoyi
Faith Adebọla, Eko Marun-un ni wọn, Yẹkinni Mohammed, ẹni ọdun mejilelaaadọta, Mukaila Tukur, ẹni ọdun mejilelogoji,…
Awọn kọsitọọmu gbẹsẹ-le ‘kinni’ kẹtẹkẹtẹ tawọn kan n ko lọ siluu oyinbo
Monisọla Saka Oriṣiiriṣii lọna lawọn eeyan wa n gba wa owo bayii, igbo, kokeeni atawọn egboogi…
Ọjọgbọn Ẹgbẹwọle di ọga agba tuntun fun Fasiti Ilọrin
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin L’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii, ni awọn alaṣẹ Fasiti Ilọrin, nipinlẹ Kwara, kede Ọjọgbọn…
Ọbabinrin Elizabeth Keji ti ku o!
Faith Adebọla Elizabeth keji, ọbabinrin to pẹ lori itẹ ju lọ lorileede United Kingdom, ti…
Rasaki atọrẹ ẹ n rin ni bebe ẹwọn, ewurẹ ni wọn lọọ ji ko ni Ijan-Ekiti
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ọwọ ẹṣọ Amọtẹkun ipinlẹ Ekiti ti tẹ ọkunrin tẹwọnde kan, Basiru Rasaki, ẹni…