Aṣiṣe nibọn wa to pa ọmọ ọdun meji n’Ilaro- Awọn aṣọbode

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ileeṣẹ aṣọbode ilẹ wa, ẹka ‘Ogun 1 Area Command’, ti ni awọn kabaamọ…

Gomina Seyi Makinde wọle pade pẹlu Ladọja, Lekan Balogun atawọn agba oye Ibadan

Ni Satide, ọjọ kẹẹẹdogun, oṣu kin-in-ni, ọdun yii, ni Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ẹnjinnia Ṣeyi Makinde, tilẹkun…

Nitori to ṣe agbere, wọn fun iyaale ile lẹgba ọgọrun-un

Ọbẹ ti baale ile ki i jẹ, iyaale ile ko gbọdọ se e ni ọrọ wọn…

 Eyi ni bi Akala ṣe fa mi goke laarin awọn olorin- Ayefẹlẹ

Ọlawale Ajao, Ibadan Gbajugbaja olorin Juju nni, Dokita Yinka Ayefẹlẹ, ti ṣalaye bi gomina ipinlẹ Ọyọ…

Mo maa n jẹ ẹya ara eeyan bii nnkan ọmọkunrin, oju, ifun ati gogongo, mo si tun maa n ta a fawọn to ba fẹ-Aminu

Aminu Baba lọkunrin to jokoo yii n jẹ, ẹnu ara ẹ lo fi jẹwọ pe oun…

Nitori ẹbun mọto tawọn ọmọ rẹ fun un lọjọọbi ẹ, Iya Fẹmi Adebayọ bu sẹkun

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Inu ẹni ki i dun ka pa a mọra, koda, eeyan a maa…

Lẹyin tawọn Fulani yii sa lọgba ẹwọn Abolongo lọwọ tẹ wọn n’Isẹyin

Olu-Theo Omolohun, Oke-Ogun. Aṣeyọri nla ni fawọn ẹṣọ fijilante ilu Isẹyin, lagbegbe Oke-Ogun, nipinlẹ Ọyọ, latari bọwọ wọn ṣe…

Isọkusọ ọrọ ni pe mo ti fọwọ si Tinubu lati dupo aarẹ – Wọle Ṣoyinka

Faith Adebọla, Eko  Onigege ara akọwe-kọwura ilẹ wa nni, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka, ti sọ pe ọrọkọrọ…

Loootọ lẹgbẹ APC ti pin si meji l’Ọṣun, ṣugbọn TOP ni mi tọkantọkan-Arẹgbẹṣọla

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ipinlẹ Ọṣun nigba kan ri, Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹṣọla, ti sọ gbangba pe…

Eyi ni ileri ti Akala ṣe fun mi ko too ku- Makinde

Ọlawale Ajao, Ibadan ‘‘Ọtunba Adebayọ Alao-Akala, gomina ipinlẹ Ọyọ to doloogbe ti iṣeleri lati ṣiṣọ loju…

Funra ijọba Ogun ni yoo yi ero rẹ pada nigba ti wọn ba n ri esi ofin ti wọn ṣe lori ọba sinsin l’Ogun-Ọba Ogboni Agba

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Laipẹ yii ni Gomina ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapọ Abiọdun, buwọ lu u pe…