O ṣẹlẹ: Alaga APC kọwe fipo silẹ l’Ondo, lo ba darapọ mọ PDP

Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress nijọba ibilẹ Ẹsẹ Odo, nipinlẹ Ondo, Samuel Ọlọrunwa, ti kọwe…

Iku tun pa aṣofin mi-in l’Ekoo o, Ọnarebu Tunde Buraimọh ti dagbere faye

Faith Adebọla, Eko A-gbọ-sọgba-nu iṣẹlẹ buruku kan niroyin ọhun, afẹmọjumọ owurọ ọjọ Ẹti, Furaidee, oni ni…

Korona pa alaga ẹgbẹ awọn dokita tẹlẹ l’Ondo

Alaga ẹgbẹ awọn dokita nipinlẹ Ondo tẹlẹ, Dokita Michael Adeyẹri, ti dagbere faye lẹyin to lugbadi…

Ija Makinde atiyawo Ajimọbi: Ajimọbi parọ buruku mọ Ariṣekọla ni o

*Aarẹ ko fun un nilẹ kankan *Ladọja paapaa kọ lo nilẹ *Ilẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ ni…

Korona: Ọjọgbọn Ibrahim ṣatilẹyin fun ẹkọ ayelujara

Stephen Ajagbe, Ilọrin Ọgba-agba Fasiti Al-Hikmah niluu Ilọrin tẹlẹ, Ọjọgbọn Mohammed Taofeek Ibrahim, ti rọ ijọba…

Ẹja panla miliọnu mẹta aabọ naira ti Ode atọrẹ ẹ ji sọ wọn dero kootu

Faith Adebọla, Eko Arokan ni wọn lo n mu ẹkun asun-un-da wa, arokan ọhun lo ṣẹlẹ…

Baba fi ibalopọ fa idi ọmọ bibi inu ẹ ya l’Akinyẹle, n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Awọn iṣẹlẹ gbankọgbi to n waye lojoojumọ nijọba ibilẹ Akinyẹle, nigboro Ibadan, la…

Ile-ẹjọ sọ awọn mẹrin to paayan sẹwọn l’Ogbomọṣọ, iya meji lo bi awọn mẹrẹẹrin

Ọlawale Ajao, Ibadan Fun bi wọn ṣe pa ọkunrin kan lai ṣẹ, lai ro, awọn ọmọ…

Ọba di meji n’Ikire: Ile-ẹjọ yọ Ọba Falabi nipo

*N lawọn idile to kan ba jawe oye le Ọlanrewaju lori *Idi ti a ko fi…

Ọbinrin ti Robbinson fipa ba lo pọ loṣu kẹrin ko ti i gbadun

*Wọn ni eegun ẹyin rẹ ti kan Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Igbobi, l’Ekoo, ni wọn ni ọmọ…

Arun Koronafairọọsi tun ti pa eeyan mẹfa mi-in ni Kwara

Stephen Ajagbe, Ilorin Lẹyin iku olori oṣiṣẹ gomina, Aminu Logun, eeyan mẹfa mi-in ni arun Korona…