Awọn ọlọpaa fibọn fọ mi lẹyin, wọn sọ mi di arọ, n ko si le bimọ mọ- Ọlasunkanmi

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta   Awọn eeyan ti ko mọ Ọgbẹni Ọlasunkanmi Fagbemi ri fẹrẹ le maa…

Awọn araalu binu si Tinubu, nitori bo ṣe ni ki wọn maa fawọn darandaran ni ilẹ ti wọn ko ba lo

Faith Adebọla       Titi di asiko yii lawọn eeyan ṣi n fi aidunnu wọn…

Igbakeji gomina Ọṣun ṣabẹwo si abule Wasinmi ti wọn ti pa eeyan mẹfa ninu mọlẹbi kan naa

Florence Babaṣọla       Kọmiṣanna ọlọpaa nipinlẹ Ọṣun, Wale Ọlọkọde, ti sọ pe ko si…

Awọn agbebọn tun ko ọmọleewe ati tiṣa lọ ni Kaduna

Faith Adebọla       Afaimọ ko ma jẹ pe awọn jaduku agbebọn yii mọ-ọn-mọ doju…

Ọwọ ti tẹ ẹni kan lori ọrọ awọn Fulani mẹfa tawọn agbebọn pa ni Waasinmi

Florence Babaṣọla   Ijọba ipinlẹ Ọṣun ti sọ lalẹ ọjọ Aje, Mọnde, ọsẹ yii, lori wahala…

Baba ọmọ to ku lọsibitu FMC, l’Abẹokuta, la aga mọ dokita lori, o ni ko tete tọju ọmọ oun lo fi ku

Adefunkẹ Adebiyi,Abẹokuta   Ko si ọrọ meji tawọn eeyan n sọ nipa ọsibitu Federal Medical Center…

Babade foju bale-ẹjọ l’Ọrẹ, oṣiṣẹ kootu lo lu lalubami

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ       Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti wọ oniṣowo epo kan ti…

Awọn ọmọ ‘Yahoo’ mẹjọ bọ sọwọ awọn EFCC l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ   Ko din lawọn ọmọ Yahoo mẹjọ ti ajọ EFCC, ẹka tipinlẹ Ọyọ,…

Ibọn meji lawọn ọlọpaa gba lọwọ awọn ọmọ ‘Yahoo’ n’Ilaro

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta   Lọjọ Ẹti, Furaidee, ọjọ kejila, oṣu kẹta yii, ni ajọ EFCC mu…

Sanwo-Olu ati Igbakeji ẹ gbabẹrẹ ajẹsara Koro

Faith Adebọla, Eko       Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Oluṣọla Sanwo-Olu, ti gba abẹrẹ ajẹsara…

Ijọba lawọn o fowo kun owo epo, wọn tọrọ aforiji lọwọ araalu

Faith Adebọla     Pẹlu bi aroye ati ariwo ṣe gba igboro kan lẹyin ti ajọ…