Orile-ede Niger yoo gbogun ti ẹnikẹni to ba fẹẹ koju ija si mi-Buhari

Monisọla Saka Pẹlu bi Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe n palẹmọ lati gbe ijọba ọdun mẹjọ rẹ…

Osisẹ Fasiti Ilọrin kan rẹwọn he, ẹsun jibiti ni wọn fi kan an

Ibrahim Alagunmu L’Ọjọ Aje, Mọnde, ọjọ kejilelogun, oṣu Karun-un yii, ni ile-ẹjọ giga kan to filu…

Peter Obi gbọdọ mu awọn eri to fẹẹ fi pe Tinubu lẹjọ wa laarin ọsẹ mẹta-Kootu

Adewale Adeoye Ile-ejọ kan to n gbọ ẹsun magomago to su yọ lakooko ibo aarẹ to…

Adajọ ju ọlọkada to lu ọlọpaa sẹwọn l’Ọsun

Adewale Adeoye Onidaajọ A. Ayaba, ti ile-ẹjọ Majisireeti kan niluu Oṣogbo, nipinlẹ Ọṣun, ti ni kawọn…

Iji lile ṣọṣẹ l’Ondo, ọpọ araalu di alainile lori

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọpọlọpọ awọn eeyan ni wọn ti di alainile lori latari iji nla kan…

Owo tẹ ayederu dokita, ẹni to ṣiṣẹ abẹ fun lo ku 

Adewale Adeoye Awọn ọlọpaa agbegbe Ọta, nipinlẹ Ogun, ti foju ayederu dokita kan, Afeez Adegoke, ẹni…

Diẹ lo ku ki tia-gaasi awọn ọlọpaa ran akẹkọọ marundinlogoji sọrun apapandodo l’Oṣogbo

Florence Babaṣọla, Osogbo Titi digba ti a n koroyin yii jọ, ileewosan ni awọn akẹkọọ marundinlogoji…

Iru ki waa leleyii, Mustapha pa lanledi rẹ nibi to ti fẹẹ fipa ba a lo pọ l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọkunrin ara Togo kan, Gbègèlè Mustapha, ti wa nikaawọ awọn ọlọpaa ipinlẹ Ondo,…

Nitori ibalopọ ati jibiti, wọn le olukọ ati oṣiṣẹ fasiti mẹtala danu

Faith Adebọla Awọn alakooso Fasiti Ambrose Ali (AAU), to wa nipinlẹ Edo, ti kede pe lẹyin…

Ọsẹ yii nile-ẹjọ to ga ju lọ maa dajọ lori iyansipo Tinubu ati Shettima

Faith Adebọla  Pẹlu bo ṣe ku ọsẹ kan pere ti wọn yoo ṣebura wọle fun aarẹ…

Ọwọ tẹ awọn meji ti wọn sa lọgba ẹwọn Kuje 

Adewale Adeoye Awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn kan ti wọn n pe ni ‘Kuje Correctional Centre’ to…