Ọwọ tẹ manija otẹẹli to fẹẹ fi tipatipa ṣe ‘kinni’ fun agunbanirọ l’Oṣogbo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Manija ileetura kan niluu Oṣogbo, Joseph Adelẹyẹ, ti n ka boroboro lagọọ ọlọpaa…

Nitori ẹsun ijinigbe, ile-ẹjọ sọ Fulani darandaran mẹfa sẹwọn gbere ni Kwara

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Lọjọ Ẹti, Furaidee, ọṣẹ yii, ni ile-ẹjọ giga kan to fi ilu Ilọrin,…

Ẹ lo anfaani oṣu Ramandan lati gbadura fun Kwara ati Naijiria-Gomina Abdulrazak

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Gẹgẹ bi wọn ṣe kede pe aawẹ awọn Musulumi, iyẹn Ramandan, yoo bẹrẹ…

Wọn ji akẹkọọ gbe ninu ọgba ileewe l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Akẹkọọ kan lawọn ajinigbe ti ji gbe lọ ninu ọgba ileewe rẹ l’Akurẹ…

Ijọba Eko ṣekilọ: Ẹ fura o, oṣu mẹwaa lojo yoo fi rọ lọdun yii

Faith Adebọla, Eko Bi ko ba ṣe’ni ri, a ki i sọ pe o tun de…

Ẹlẹrii to kẹyin jẹrii gbe Baba Ijẹṣa ni kootu

Faith Adebọla Ẹlẹrii to kẹyin ninu ẹjọ ifipa ba ni lo pọ ti gbajugbaja onitiata ati…

Kayeefi, aara san pa awọn ọdọ marun-un l’Agọọ Dada, Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Titi di asiko yii niroyin iku awọn ọdọ marun-un ti aara san pa…

Awọn ọlọpaa ti mu Musa o, iya ẹni ọdun marundinlọgọrin lo fipa ba lo pọ titi tiyẹn fi ku mọ ọn labẹ

Ile-ejọ ni ọmọkunrin kan, Iliya Musa ti ko ju ẹni ọdun mejilelọgbọn lọ, to lọọ fipa…

Ṣe gbogbo yin ti ri idi ti mo ṣe ta ko iyansipo Buhari lọdun 2015 bayii – Fayoṣe

Faith Adebọla “Emi ni mo pariwo ju lọ, ti mo ta ko iyansipo Muhammadu Buhari funpo…

Hassan, ọmọ ọdun mẹtadinlogun, yọ oju Yunusa, o ni oogun afẹẹri loun fẹẹ fi ṣe

Faith Adebọla Bi ki i baa ṣe kọmiṣanna ọlọpaa lo sọrọ ọhun ninu atẹjade to fi…

Oyetọla ni ile-ẹkọ awọn olukọni agba niluu Ileṣa yoo di fasiti laipẹ

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ipinlẹ Ọṣun, Alhaji Gboyega Oyetọla, ti kede mimu agbega ba ile-ẹkọ olukọni…