Ọrọ Musulumi meji to fẹẹ dupo aarẹ ati igbakeji ko ba ilana Ọlọrun mu – Dogara

Monisọla Saka Abẹnugan ile-igbimọ aṣofin ilẹ wa nigba kan, Yakubu Dogara, ti sọrọ l’Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ…

Lẹyin ọsẹ meji tawọn eleyii tẹwọn de ni wọn tun lọọ jale l’Ẹgbẹda

Monisọla Saka, Eko Lẹyin ti wọn ja mọto meji gba loju ọna Ẹgbẹda, nipinlẹ Eko lọwọ…

Eyi ni awọn amuyẹ ti ẹni to ba fẹẹ jẹ Alaafin gbọdọ ni – Baba Iyaji

Ọlawale Ajao, Ibadan Ko din ni eeyan mọkandinlọgọfa (119) to ti n jijadu bayii lati di…

Mo mọ Tinubu daadaa, ẹni ọdun mẹrindinlaaadọrun ni, ko le dari Naijiria -Tee Mac 

Monisọla Saka Gbajugbaja ọkunrin to maa n fọ fere, to tun figba kan jẹ aarẹ ẹgbẹ…

Nitori kawọn oṣiṣẹ le gba kaadi idibo, ijọba Kwara kede ọjọ Ẹti ni isinmi lẹnu iṣẹ

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Lati ri i pe gbogbo awọn olugbe ipinlẹ Kwara ti wọn ti to…

Epo ti Emmanuel ko sinu mọto lo gbina lojiji to fi jona ku n’llọrin 

Ibrahim Alagunmu Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ yii, ni arakunrin dẹrẹba ẹni ọdun mẹtadinlogoji kan, Emmanuel, pade iku…

Ọpọ eeyan fara gbọta ninu akọlu to tun waye l’Ọwọ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọpọ eeyan la gbọ pe wọn fara gbọta ninu akọlu tuntun mi-in tawọn…

Ọmọ ti Itunu bi ku, lo ba lọọ ji ọmọọlọmọ gbe lati fi rọpo oku ọmọ rẹ n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti tẹ obinrin ẹni ọdun mẹtalelogun (23) kan,…

Ọmọọba Saka Adelọla Matẹmilọla di Olowu tuntun

Gbenga Amos, Abẹokuta Ọrọ yiyan ọba tuntun sori apere Olowu tilẹ Owu ti ditan wayi, wọn…

Ẹ tun ero yin pa lori fifofin de ọkada gigun lorileede Naijiria – Oluwoo

 Florence Babaṣọla, Oṣogbo Nitori ipinnu ijọba apapọ lati fofin de ọkada gigun kaakiri orileede yii, Ọba…

Eyi lawọn ọmọ igbimọ ti yoo ṣeto gbigba iṣakoso ipinlẹ Ọṣun fun Adeleke

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina tuntun nipinlẹ Ọṣun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke, ti gbe igbimọ ẹlẹni mẹtadinlogoji ti…