Saheed Oṣupa kawe gboye ni Yunifasiti Ibadan

Adefunkẹ Adebiyi Ni bayii, bi wọn ba n pe awọn to kẹkọọ gboye ni yunifasiti, Ọba…

Lawrence to fọmọ ẹ loyun gbadajọ ẹwọn gbere, lo ba bu sẹkun ni kootu

Faith Adebọla, Eko Igbe o daa lẹnu agbalagba, ṣugbọn ọdaran ẹni ọdun mẹjilelogun ti wọn porukọ…

Latari akọlu awọn Fulani darandaran, Akeredolu bẹbẹ fun atilẹyin awọn ọba alaye

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Lori akọlu tawọn Fulani darandaran n ṣe sawọn eeyan agbegbe kan nipinlẹ Ondo,…

Awọn ọlọpaa ti fi pampẹ ofin gbe Oluwọle ti ale rẹ ku mọ lọwọ l’Oke-Igbo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọkunrin ẹni ogoji ọdun kan, Ọlasunkami Oluwọle, ti wa ni ikawọ awọn ọlọpaa…

Ẹ yee bu ẹnu atẹ lu awọn aṣeyọri iṣejọba Aarẹ Buhari-Oluwoo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oluwoo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, ti gboṣuba fun oniruuru iṣẹ…

Lori ipese amayedẹrun, ọga nijọba Buhari yii lẹgbẹẹ ijọba Amẹrika-Faṣọla

Faith Adebọla  Minisita fun iṣẹ ode ati eto ile gbigbe nilẹ wa, Amofin agba Babatunde Raji…

Pasitọ Timothy ti jẹwọ l’Abẹokuta o: Loootọ ni mo n ba iya atawọn ọmọ ẹ meji lo pọ

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Pasitọ Timothy Oluwatimilẹyin ree, oludari ijọ Spirit Filled International Christian Church, Olomoore, l’Abẹokuta.…

Ọba Oluwadare Adepọju Adesina, Deji Akurẹ ti wọn rọ loye nigba kan ti waja 

Oluṣẹyẹ Iyiade,  Akurẹ Deji ilu Akure ti wọn rọ loye nigba kan, Ọba Adeṣina Oluwadare Adepọju…

Ọwọ ọlọpaa tẹ tọọgi oṣelu meji n’Ijero-Ekiti

Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti kede pe ọwọ ti tẹ awọn janduku meji…

Fathia Balogun fẹẹ ṣọjọọbi, ‘wan fifti taosan’ (150, 000) laṣọ ẹbi

Adefunkẹ Adebiyi, 150, 000) Abẹokuta ‘Fathia Unusual 2022’ ni wọn pe e, iyẹn Fathia to yatọ si…

Wọn lara Tinubu o tun ya o, o ti pada si London fun itọju

Faith Adebọla, Eko Ọrọ kan to n ja ranyin lori ẹrọ ayelujara lasiko yii ni pe…