Faith Adebọla, Eko Ori lo ko awọn olugbe ile kan lagbegbe Ibẹju-Lẹkki, nipinlẹ Eko, yọ, diẹ…
Author: Alaroye
Ọwọ ọlọpaa tẹ mẹrinla ninu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to n yọ wọn lẹnu n’Ikorodu
Faith Adebọla, Eko Mẹrinla lara awọn afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun ‘Aiye’ to n da wahala silẹ…
Awọn tọọgi kọju ija sira wọn l’Ejigbo, ni wọn ba yinbọn pa Abeeb
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọmọdekunrin kan, Abeeb Abifarin, lo ti jẹ Ọlọrun nipe laago mẹjọ ku diẹ…
Awọn aṣofin Eko buwọ lu eto iṣuna ọdun 2021
Faith Adebọla, Eko Ile-igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ti buwọ lu tiriliọnu kan, miliọnu mẹtalelọgọjọ naira (#1.163…
Nitori ere asapajude, ajọ ẹsọ oju popo mu mọto akero marundinlogoji
Jide Alabi Ileeṣẹ ijọba to n mojuto irinna ọkọ loju popo (FRSC), Ọgbẹni Oluṣẹgun Ogungbemide, ti…
Awọn aṣofin ti bura fun Ọbafẹmi to gba’po Tunde Buraimọh l’Ekoo
Faith Adebọla, Eko Nibi ijokoo wọn to gbẹyin lọdun yii, lawọn aṣofin Eko ti bura fun…
Aago mọkanla alẹ ni ki gbogbo ṣọọṣi pari isin aisun ọdun tuntun l’Ekoo – CAN
Faith Adebọla, Eko Ẹgbẹ awọn ẹlẹsin Kristẹni, Christian Association of Nigeria, (CAN), ẹka ti Eko, ti…
Alaga ẹgbẹ oṣelu Labour, Alaaji Abdulsalam, ti ku o
Faith Adebọla Alaga apapọ fun ẹgbẹ Labour Party, Alaaji Abdulkadir Abdulsalam, ti dagbere faye. Owurọ ọjọ…
Ọwọ ọlọpaa tẹ ọkan ninu awọn to dana sun eeyan meji n’Ibadan
Ọlawale Ajao, Ibadan Ki wọn maa dana sun eeyan ti waa fẹẹ di aṣa awọn araalu…
Awọn ọba Akoko gba ijọba nimọran lori eto aabo to mẹhẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn ọba alade kan l’Akoko ti pa ẹnu pọ lati gba ijọba apapọ…
Happiness tawọn ajinigbe ji l’Ekiti ti gba ominira
Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Ọkunrin kan tawọn ajinigbe ji lọjọ ọdun Keresi, Happiness Ajayi, ti gba ominira…