Monisọla Saka Koju ma ribi, gbogbo ara loogun ẹ lawọn akẹkọọ Poli Ilaro fi ọrọ naa…
Category: Ìròyìn
Tori bi awọn akẹkọọ ṣe fipa ba ẹlẹgbẹ wọn lo pọ, ijọba ti ileewe Chrisland pa l’Ekoo
Faith Adebọla, Eko Ijọba ipinlẹ Eko ti fi agadagodo gbangba sẹnu ọna to wọ ọgba ileewe…
Awọn agbebọn yinbọn pa awakọ nibi to ti n sa fawọn ajinigbe l’Akunnu Akoko
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọpọ awọn eeyan ilu Ajọwa Akoko, nijọba ibilẹ Ariwa Iwọ-Oorun Akoko, ni wọn…
Awọn ọmọlẹyin Akeredolu binu sawọn to n gbe iroyin iku rẹ kiri
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ko jọ epe, bẹẹ ni ko jọ aṣẹ, lo n jade lati ẹnu…
Iya mi lo maa n ro mi lagbara nigbakuugba ta a ba fẹẹ lọọ digunjale- Timileyin
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Kayeefi nla lo jọ loju awọn to wa nibi ti ọmọdekunrin ẹni ọdun…
Awọn Fulani kọ lu baba agbẹ ninu oko rẹ n’Ikakumọ Akoko, wọn gun un yannayanna
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Baba ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin kan, Alagba Babatunde Benjamin, lori tun ko yọ lọwọ…
Ẹgbẹ APC yoo ṣepade lori eto idibo abẹle wọn ni ogunjọ, oṣu Kẹrin
Monisọla Saka Ẹgbẹ All Progressive Congress (APC), ti fẹnu ko lati pade ni ogunjọ, oṣu Kẹrin,…
Awọn alakooso LCC sun ọjọ ti wọn yoo bẹrẹ si i gbowo ni toogeeti Lekki siwaju
Monisola Saka, Eko Lẹyin ọpọlọpọ ijiroro pẹlu awọn lookọ lookọ, ileeṣẹ to n mojuto toogeeti to…
Ọwọ tẹ Ṣakiru atọrẹ ẹ lasiko ti ọn fee ji ọmọ meji gbe ni ṣọọṣi Sẹlẹ l’Abẹokuta
Gbenga Amos, Abẹokuta Bo tilẹ jẹ pe ori ko afurasi ọdaran ti wọn porukọ ẹ ni…
Ọmọọdun mẹtadinlogun gun ọga ẹ pa, ibi to ti fẹẹ ta mọto ẹ to ji lọwọ ti tẹ ẹ ni Benin
Faith Adebọla Wọn lọjọ ori ọmọkunrin yii ko ju mẹtadinlogun lọ, ṣugbọn iwa buruku to hu…
Tori ifipabanilopọ, wọn sọ Micheal sẹwọn gbere l’Ekoo
Faith Adebọla, Eko Pẹlu bi agbẹjọro Ahmed Micheal, baale ile ẹni ọdun mẹtalelọgbọn ti wọn fẹsun…