Faith Adebọla Kaka ki ewe agbọn dẹ, koko lo n le si i lọrọ awọn janduku…
Nitori ẹsun jibiti, adajọ sọ akẹkọọ Kwara Poli ati akẹgbẹ ẹ sẹwọn n’llọrin
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọṣẹ yii, nile-ẹjọ giga kan niluu Ilọrin, nipinlẹ Kwara, sọ…
Ko ti i ju oṣu mẹjọ lọ ti mo bẹrẹ iṣẹ jija foonu gba, Emeka ni mo maa n ta a fun n’Ikẹja-Balogun
Faith Adebọla, Eko Ọlajide Balogun lorukọ ọkunrin ẹni ọdun mẹrindinlogoji to wa ninu fọto yii, ọmọ…
Ijọba o gbọdọ fun ẹnikẹni labẹrẹ ajẹsara Korona ni tipatipa-Ile-ẹjọ lo sọ bẹẹ
Faith Adebọla Ile-ẹjọ giga apapọ kan to fikalẹ siluu Port-Harcourt, nipinlẹ Rivers, ti sọ pe ọrọ…
Buhari le awọn minisita meji danu, o yan awọn mi-in dipo wọn
Faith Adebọla Meji lara awọn minisita to n ba ijọba apapọ ṣiṣẹ, Minisita lori feto ọgbin,…
Nitori tọkọ-tiyawo ti wọn ji gbe, awọn eeyan fẹhonu han l’Ekiti
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ni kutukutu owurọ ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọsẹ yii, ni awọn ajinigbe tun ji…
Awo ounjẹ lọmọọdọ yii fọ, lọga ẹ ba fipa rọ ata si i lọfun
Faith Adebọla Obinrin kan ti wọn porukọ ẹ ni Ojuigo David ti wa lahaamọ awọn ọlọpaa…
Kootu gbẹsẹ le apo ikowosi ati ile Bidemi Rufai, ọmọọṣẹ Dapọ Abiọdun tẹlẹ
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ile-ẹjọ giga kan nipinlẹ Eko ti gbẹsẹ le apo ikowosi Abidemi Ganiu Rufai,…
Awọn agbebọn ṣeku pa olori awọn Fulani labule kan ni Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Awọn agbebọn ti ṣeku pa olori awọn Fulani, Alhaji Alhaji Sheidu Madawaki, labule…
Nitori bi eto aabo to dẹnukọlẹ, ijọba ṣepade pẹlu awọn adari Fulani ni Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrazaq, ti ṣepade pẹlu awọn adari Fulani nipinlẹ naa…
Ọwọ ọlọpaa tẹ Fulani ajinigbe meji, wọn pa ọkan, wọn mu ekeji laaye n’Imala
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokutan Niṣe lo jọ pe awọn ajinigbe atawọn ọlọpaa ti jọ pinnu pe awọn…