Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ. Iyalẹnu nla lo jẹ fawọn eeyan ipinlẹ Ondo nigba ti wọn ri orukọ…
Onibaara lu alagbe ẹgbẹ ẹ pa l’Ekoo, o lo n yọju wo abẹ oun nigba toun n tọ
Faith Adebọla, Eko Iyalẹnu gbaa niṣẹlẹ aburu kan to waye lagbegbe Victoria Island, l’Ekoo, yii jẹ…
Lẹyin ọjọ mọkanla, Fayẹmi bọ lọwọ Korona
Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Lẹyin ọjọ mọkanla ti Gomina Kayọde Fayẹmi tipinlẹ Ekiti ti ni arun Koronafairọọsi,…
Nitori ibo Ondo to n bọ, Akeredolu ṣabẹwo si Tinubu
Ibo ti won yoo di ni ipinlẹ Ondo lati yan gomina tuntun ko ju oṣu meji…
Awọn Boko Haram kọ lu gomina, diẹ lo ku ki wọn mu un
Ọlọrun lo yọ Gomina Ipinlẹ Borno o. Gomina Babagana Zulum n pin ounjẹ kaakiri awọn adugbo…
Wọn ni ọdẹ ori lo n yọ ṣọja to yinbọn pa ọga ẹ ni Borno lẹnu
Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Ṣọja kan ti ileeṣẹ ologun ilẹ wa ko darukọ rẹ ti yinbọn pa…
Maṣinni ti wọn fi n ṣe ọṣẹ lo ge akẹkọọ Fasiti Ibadan yii si wẹwẹ nibi to ti n ṣiṣẹ
Titi di ba a ṣe n sọ yii lawọn eeayn ṣi n tara ikunlẹ abiyamọ lori…
Ẹ woju Pasitọ Adetokunbọ to jiiyan gbe ninu ṣọọṣi ẹ ni Ṣagamu, o ni koun le rowo ẹran Ileya fawọn alaini ni
Kayeefi ni ọrọ naa jẹ o. Ohun to si ṣe jẹ kayeefi ni pe pasitọ ni…
O ma ṣe o, Oloye Ayọ Fasanmi ti ku o
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọkan pataki ninu awọn aṣaaju Yoruba, to tunjẹ ọkan ninu awọn olori ẹgbẹ…
Nitori bi wọn ko ṣe fun un ni tikẹẹti ni PDP, Agboola Ajayi fẹẹ dara pọ mọ ẹgbẹ ZLP
Igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agbọọla Ajayi, ti ko ọrọ rẹ to sọ lọsẹ to kọja pe…
O ma ṣe o, wọn ni Ọlabọde luyawo ẹ pa toyuntoyun l’Akurẹ
Awọn ọlọpaa ti mu ọkunrin kan ti wọn n pe ni Oluwaṣeun Ọlabọde o. Ẹsun pe…