Lẹyin ọsẹ mẹta ti Ajimọbi ku ni kọmiṣanna rẹ ku sinu ijamba mọto

Ọlawale Ajao, Ibadan Lẹyin ọsẹ mẹta ti gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi ku, ọkan…

Ko sẹni to yọ orukọ mi kuro ninu awọn oludije – Akeredolu

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu, ti ni ko si ootọ ninu ahesọ to n…

Ibanikẹdun n rọ bii ojo nipinlẹ Ogun, ọba mẹta lo waja laarin ọsẹ kan

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bo tilẹ jẹ pe agbalagba ni wọn, ti ko si eyi to ṣanku…

Lẹyin ọjọ mẹwaa nigbele, akọwe ijọba ipinlẹ Ọṣun bọ lọwọ arun Koronafairọọsi

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Akọwe ijọba ipinlẹ Ọṣun, Ọmọọba Wọle Oyebamiji, ti jajabọ lọwọ arun Koronafairọọsi bayii.…

Wọn ṣi n wa awọn eeyan tawọn ajinigbe ji gbe lọ l’Ekiti

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Lalẹ ọjọ Ẹti, Furaidee, lawọn ajinigbe kan ti wọn to mẹwaa ya bo…

Ọda owo ati ailera ni ko jẹ ki n ṣayẹyẹ ọgọrin ọdun ti mo dele aye – Lanrewaju Adepọju

Ọlawale Ajao, Ibadan Lọjọ Iṣẹgun,Tusidee, ọsẹ to kọja, lakewi agbaye nni, Alhaji Ọlanrewaju Adepọju, pe ẹni ọgọrin ọdun laye.…

Nitori ajẹsilẹ owo-oṣu, awọn oṣiṣẹ fẹẹ gbena woju Akeredolu l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ  Awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣiṣẹ ipinlẹ Ondo ti fẹhonu wọn han si gomina ipinlẹ…

Olu Imaṣayi, Ọba Gbadebọ Oni, ti waja

Olu Imaṣayi, Ọba Gbadebọ Oluṣọla Oni, ti waja. Akọwe iroyin fun Gomina Dapọ Abiọdun, Ọgbẹni Kunle…

Ibo abẹle APC l’Ondo: Eyi ni orukọ awọn ti yoo kopa

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Mọkanla ninu awọn oludije sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu APC ipinlẹ Ondo ni…

Lori iyọnipo igbakeji gomina, adajọ-agba Ondo ja ireti awọn aṣofin kulẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Adajọ-agba ipinlẹ Ondo, Abilekọ Oluwatoyin Akeredolu, ti ja ireti awọn ọmọ ile igbimọ…

O ṣẹlẹ: Alaga APC kọwe fipo silẹ l’Ondo, lo ba darapọ mọ PDP

Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress nijọba ibilẹ Ẹsẹ Odo, nipinlẹ Ondo, Samuel Ọlọrunwa, ti kọwe…