Muhammadu to fipa ba ọmọ ọdun mẹwaa lo pọ n’Ilọrin ni iṣẹ eṣu ni

Stephen Ajagbe, Ilorin   Afurasi kan, Muhammadu Mailemu, to n gbe laduugbo Banni, lagbegbe Sango, niluu…

Nitori ṣọja atawọn mi-in ti wọn ji gbe, awọn agbofinro ya lu igbo ọna Ibadan s’Ijẹbu-Ode 

Ọlawale Ajao, Ibadan   Ba a ṣe n wi yii, inu igbo ni ikọ oluwadii laarin…

Ọọni yan Toyin Kọlade ni Iyalaje Oodua

Florence Babaṣọla   Ọọni Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, ti kede oludari apapọ ọdun Aje, Ọmọọbabinrin…

Awọn ajinigbe tun ji soja atawọn meji mi-in gbe n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan   Ọrọ awọn ajinigbe nipinlẹ Ọyọ bọna mi-in yọ lọsẹ yii pẹlu bi…

Ọpẹ o, wọn ti ri dokita ati nọọsi ti wọn ji gbe n’Imẹkọ gba pada

Adebiyi Adefunkẹ, Abẹokuta   Dokita Ọladunni Ọdẹtọla ati Nọọsi Bamgboṣe tawọn ajinigbe ji l’Ọjọruu Wẹsidee, ọsẹ…

Wọn ba ageku ara Iya Ganiya Elekuru ninu ile babalawo n’Ileefẹ

Florence Babaṣọla Kayeefi lọrọ naa ṣi n jẹ fun awọn eeyan agbegbe Irẹmọ, niluu Ileefẹ, pẹlu…

Derrick fada ge ọwọ ọmọbinrin yii bọ nitori ko gba ko fipa ba a lo pọ

Ko si idi kan fun ọmọdebinrin yii, Evelyn Namasopo, ọmọ ọdun mẹrindinlogun (16)lati padanu ọwọ rẹ…

Ewurẹ mẹwaa lawọn ọrẹ meji yii lọọ ji gbe niluu igẹmọ-Ekiti

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Iwadii ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti bẹrẹ lori awọn afurasi meji kan tọwọ…

Awọn ajinigbe ji oniṣowo epo bẹntiroolu n’Iṣan-Ekiti

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Lẹyin oṣu mẹta tawọn ajinigbe kan ji oloye ẹgbẹ awọn oniṣowo epo bẹntiroolu…

Nitori adigunjale tawọn ọdọ lu pa s’aduugbo wọn, baale ile mẹta dero ahamọ n’Ikọtun

Faith Adebọla, Eko       Ahamọ awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ lawọn baale ile mẹta kan ti…

Wọn ji dokita ati nọọsi gbe loju ọna Abẹokuta s’Imẹkọ

Adefunkẹ Adebiyi,Abẹokuta  Dokita agba lọsibitu Jẹnẹra Imẹkọ-Afọn, Ọladunni Ọdẹtọla, ati nọọsi kan, Abilekọ Bamgboṣe, ti wa…