Kayeefi: Wọn ji alaga ẹgbẹ PDP gbe sa lọ

Adewale Adeoye Titi di asiko ta a n koroyin yii jọ, inu ahaamọ awọn ajinigbe ni alaga ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ…

Wọn ti mu Ojo to n dibọn bii alaarun ọpọlọ, aṣe adigunjale ni

Adewale Adeoye Teṣan ọlọpaa agbegbe Isọkoko, ni Agege, nipinlẹ Eko, ni Ọgbẹni Ọlasẹinde Ojo ti wọn mu fun ẹsun pe o n dibọn bii ẹni ti ko…

O doju ẹ, awọn agbebọn tu ji araalu mẹrinla gbe sa lọ nipinlẹ Kaduna

O doju ẹ, awọn agbebọn tu ji araalu mẹrinla gbe sa lọ nipinlẹ Kaduna Adewale Adeoye Paroparo ni…

Idajọ oju-ẹsẹ, awọn araalu binu dana sun afurasi adigunjale kan

Idajọ oju-ẹsẹ, awọn araalu binu dana sun afurasi adigunjale kan Adewale Adeoye Titi di asiko ta a n…

O ma ṣe o! Onimọto to ba ọkọ ọkunrin yii jẹ tun pa a danu

Monisọla Saka Iya ọna meji lo jẹ ọkunrin ẹni ọdun mẹtalelọgbọn (33) kan, Ọgbẹni Ṣeun Sahola,…

Iku Oloye Bọla Ige ti wọn ni mo lọwọ ninu rẹ, eyi ni b’ọrọ ṣe jẹ-Sunday Igboho

Adewale Adeoye ‘’Irọ buruku ni wọn pa mọ mi. Emi o lọwọ ninu iku Oloye Bọla…

Eyi le o! Obinrin yii ji ara ẹ gbe, o loun fẹẹ fi gbowo lọwọ ẹgbọn oun ni

Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom, ti tẹ obinrin kan, Imaobong Sampson, to parọ pe wọn…

Nnkan de! Wọn ba oku sifu difẹnsi ninu kanga l’Ọṣun

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oṣiṣẹ ajọ sifu difẹnsi kan ti wọn ti n fi ọpọlọpọ ọjọ wa…

Kayeefi! Lasiko ti dẹrẹba yii n wakọ lọ ku lojiji ni Fasiti Ilọrin 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Inu ibanujẹ ati ọfọ ni mọlẹbi Lukman to jẹ dẹrẹba, to n fọkọ…

Peter yii ma daju o, laarin ọjọ meje ti wọn gba a siṣẹ lo pa ọga ẹ l’Ekoo

Inu ibanujẹ lawọn mọlẹbi ati aladuugbo mama kan ti ko ti i sẹni to mọ orukọ…

Ko saaye fun gomina lati maa fi ẹni to ba wu u jẹ alaga kansu mọ ni ipinlẹ Ọyọ -Alaga OYSIEC

Ọlawale Ajao, Ibadan Ko ni i ṣee ṣe fawọn gomina ipinlẹ Ọyó lati maa yan ẹni…