Adewale Adeoye Ọdọ awọn ọlọpaa ipinlẹ Eko ni Omidan Linda Ihebinike wa bayii to ti n gbatẹgun. Eyi ko sẹyin…
Category: Ìròyìn
Iyawo fẹẹ pa ọkọ rẹ nitori ko ma baa san gbese to jẹ ẹ
Adewale Adeoye Ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe Rafin-Guza, nipinlẹ Kaduna, ti lawọn maa too bẹrẹ iwadii nipa ẹsun ti wọn fi kan iyaale…
O ma ṣe o, obinrin yii ṣubu lule lasiko to n kọrin ẹmi ni ṣọọṣi, lo ba ku
Adewale Adeoye Ṣe lọrọ ọhun di bo o lọ yago fun mi ninu ijọ Ọlọrun kan ti wọn n…
Adanu nla ni iku Ọba Ọlalekan Balogun jẹ fun iran wa – Yoruba Obas Forum
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Agbarijọpọ awọn lọbalọba nilẹ Yoruba, labẹ Yoruba Obas Forum (YOF), ti ranṣẹ ibanikẹdun…
Kabiesi pe ipade igbimọ Olubadan lọjọ ti wọn jade laye- Ẹkẹrin Olubadan
Ọlawale Ajao, Ibadan Ẹni to ko gbogbo eeyan mọra l’Ọba Lekan Balogun. Ki i ṣe ọba…
Eyi nidi ti mi o ṣe gba awọn eeyan laaye lati maa ri Ọba Balogun mọ- Sẹnetọ Kọla Balogun
Ọlawale Ajao, Ibadan Mo dupẹ fun igbesi aye Kabiesi ati iru eeyan ti wọn jẹ. Wọn…
Ọlọrun ṣe ojuṣaaju fun Ọba Balogun- Sẹnetọ Rashidi Ladọja
Ọlawale Ajao, Ibadan Ki i ṣe gbogbo eeyan l’Ọlọrun maa n ṣe iru oore to ṣe…
Ko si ohun ti wọn fẹ lọjọ Tọsidee ti ki i tẹ wọn lọwọ- Olori Khalifat Lekan Balogun
Ọlawale Ajao, Ibadan Kabiesi jẹ oniwa rere eeyan to maa n ba gbogbo eeyan ṣawada pupọ.…
Wọn ti sọ tẹlẹ pe ọjọ Tọsidee lawọn maa ku- Olori Funmilayọ Balogun
Ọlawale Ajao, Ibadan Baba jẹ ẹni to maa n ṣaanu, to si nifẹẹ gbogbo eeyan lọkan.…
Abami ẹda l’Olubadan eyi laṣiiri bo ṣe sọ asọtẹlẹ nipa ọjọ to maa ku-Olori Ọlayinka Balogun
Ọlawale Ajao, Ibadan Pẹlu bi oriṣiiriṣii eeyan ṣe n sọ awọn ohun ti wọn mọ nipa…
Muhammad mura bii obinrin, o fẹẹ wọnu ile awọn akẹkọọ-obinrin ni Kano
Adewale Adeoye Ọdọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ajọ sifu difẹnsi ‘Nigeria Security And Civil Defence Corp’ (NSCDC), ẹka tipinlẹ Kano, ni Ọgbẹni Muhammad Munzali, ẹni ọdun marundinlogoji, to n gbe lagbegbe Kaura-Gidan-Damo, nijọba ibilẹ Shanono, nipinlẹ Kano, wa bayii.…