Ilẹ mọ ba eleyii, ayederu owo Naira lo fẹẹ na fun oni POS

Adewale Adeoye Ọdọ awọn ọlọpaa ipinlẹ Eko ni Omidan Linda Ihebinike wa bayii to ti n gbatẹgun. Eyi ko sẹyin…

Iyawo fẹẹ pa ọkọ rẹ nitori ko ma baa san gbese to jẹ ẹ

Adewale Adeoye Ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe Rafin-Guza, nipinlẹ Kaduna, ti lawọn maa too bẹrẹ  iwadii nipa ẹsun ti wọn fi kan iyaale…

O ma ṣe o, obinrin yii ṣubu lule lasiko to n kọrin ẹmi ni ṣọọṣi, lo ba ku

Adewale Adeoye Ṣe lọrọ ọhun di bo o lọ yago fun mi ninu ijọ Ọlọrun kan ti wọn n…

Adanu nla ni iku Ọba Ọlalekan Balogun jẹ fun iran wa – Yoruba Obas Forum

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Agbarijọpọ awọn lọbalọba nilẹ Yoruba, labẹ Yoruba Obas Forum (YOF), ti ranṣẹ ibanikẹdun…

Kabiesi pe ipade igbimọ Olubadan lọjọ ti wọn jade laye- Ẹkẹrin Olubadan  

 Ọlawale Ajao, Ibadan Ẹni to ko gbogbo eeyan mọra l’Ọba Lekan Balogun. Ki i ṣe ọba…

Eyi nidi ti mi o ṣe gba awọn eeyan laaye lati maa ri Ọba Balogun mọ- Sẹnetọ Kọla Balogun 

Ọlawale Ajao, Ibadan Mo dupẹ fun igbesi aye Kabiesi ati iru eeyan ti wọn jẹ. Wọn…

Ọlọrun ṣe ojuṣaaju fun Ọba Balogun- Sẹnetọ Rashidi Ladọja

Ọlawale Ajao, Ibadan Ki i ṣe gbogbo eeyan l’Ọlọrun maa n ṣe iru oore to ṣe…

Ko si ohun ti wọn fẹ lọjọ Tọsidee ti ki i tẹ wọn lọwọ- Olori Khalifat Lekan Balogun

Ọlawale Ajao, Ibadan Kabiesi jẹ oniwa rere eeyan to maa n ba gbogbo eeyan ṣawada pupọ.…

Wọn ti sọ tẹlẹ pe ọjọ Tọsidee lawọn maa ku- Olori Funmilayọ Balogun

Ọlawale Ajao, Ibadan Baba jẹ ẹni to maa n ṣaanu, to si nifẹẹ gbogbo eeyan lọkan.…

Abami ẹda l’Olubadan eyi laṣiiri bo ṣe sọ asọtẹlẹ nipa ọjọ to maa ku-Olori Ọlayinka Balogun

Ọlawale Ajao, Ibadan Pẹlu bi oriṣiiriṣii eeyan ṣe n sọ awọn ohun ti wọn mọ nipa…

Muhammad mura bii obinrin, o fẹẹ wọnu ile awọn akẹkọọ-obinrin ni Kano

Adewale Adeoye Ọdọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ajọ sifu difẹnsi ‘Nigeria Security And Civil Defence Corp’ (NSCDC), ẹka tipinlẹ Kano, ni Ọgbẹni Muhammad Munzali, ẹni ọdun marundinlogoji, to n gbe lagbegbe Kaura-Gidan-Damo, nijọba ibilẹ Shanono, nipinlẹ Kano, wa bayii.…