LONI-IN, AKEREDOLU YOO KOJU AWỌN ALATAKO Ẹ NINU APC L’ONDO

Boya Arakunrin Rotimi Akeredolu yoo tun ṣe gomina ipinlẹ Ondo lẹẹkan si i tabi ala ti…

FA Cup: Arsenal ati Chelsea yoo koju ara wọn fun aṣekagba

Oluyinka Soyemi Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ati Chelsea yoo pade nibi aṣekagba idije FA Cup lọjọ kin-in-ni,…

Tẹgbọn-taburo dero ẹwọn, igbo ni wọn ka mọ wọn lọwọ n’Ileefẹ  

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ṣebi ọmọ-iya meji ki i ṣe owo aipe lawọn agbalagba maa n wi,…

Ẹ WOJU Ẹ: ẸNI TO PA TOLULỌPẸ AFẸRONPILEENI-JAGUN REE O

Ileeṣẹ ologun ofurufu ilẹ wa ti kede, lọṣan-an yii, oruko ẹni to pa Tolulọpẹ Arotile, ọmọbinrin…

Ileeṣẹ agunbanirọ fiya jẹ mọkanla ninu wọn to n sa lẹnu iṣẹ

 Ọlawale Ajao, Ibadan  Yatọ si awọn meji to j’Ọlọrun nipe lasiko ti wọn n ṣiṣẹ sin…

Iru ki waa leleyii! Sherifat n mura idanwo Wayẹẹki lọwọ lo fi binu para ẹ n’Ikorodu

 Faith Adebọla Orin wo la fẹẹ kọ si gbẹdu lọrọ da pẹlu bi ibanujẹ ati ọgbẹ…

O TAN! ARUN KORONA TI MU MINISITA BUHARI O

Ọkan ninu awọn minisita ti wọn n ba Aarẹ Muhamadu Buhari ṣiṣẹ ninu jjọba rẹ yii…

Nilẹ Zambia, eeyan mejidinlọgbọn ko Koronafairọọsi ni kilọọbu kan

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Ṣe lawọn alaṣẹ liigi ilẹ Zambia to yẹ ko bẹrẹ lọjọ Abamẹta, Satide,…

‘A FẸẸ MỌ IKU TO PA ỌMỌ WA O,’ AWỌN YORUBA KOGI BINU

Ọrọ iku to pa ọmọọbinrin afẹronpileeni-jagun, Tolulọpẹ Arotile, ko ti i tan nilẹ rara, nitori iruju…

Oṣiṣẹ wa to ba gbowo ẹyin atẹni to fun un yoo foju bale-ẹjọ-FRSC

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ajọ ẹṣọ alaabo oju popo (FRSC), ti kede pe eyikeyii ninu awọn oṣiṣẹ…

KO SAAYE ỌDUN IBILẸ KANKAN NI GBOGBO EKITI BAYII O

Gbogbo ọdun ibilẹ pata ni wọn ti fi ofin de ni ipinlẹ Ekiti bayii o. Bo…