Tọkọ-taya lọọ ji ọkan ninu awọn ibeji gbe lọsibitu, wọn lawọn n wa ọmọkunrin dandan

Ti o ba jẹ pe aṣiri tu, diẹ lo ku kawọn tọkọ-taya ọran yii sọ idunnu…

O ma ṣe o, ‘Dudu Heritage’, ọkọ Bimbọ Ọshin, ku lojiji

Ajalu buruku ni iku iku Ọla Ibironkẹ ti gbogbo eeyan mọ si Dudu Heritage to jẹ…

Awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun pa ara wọn l’Oṣogbo, mẹwaa lara wọn lọwọ ọlọpaa ti tẹ

Florence Babaṣọla Ọmọkunrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Aniyikaye lawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ti…

Wọn ti mu ọlọpaa to yinbọn pa Mọnsurat n’Ijẹṣatẹdo

Faith Adebọla, Eko Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti rawọ ẹbẹ sawọn mọlẹbi ọmọbinrin ẹni ọdun mejidinlogun…

Awọn ọba alaye ṣewọde l’Ekiti, nitori ijọba ibilẹ tuntun ti Fayemi gbe kuro lọdọ wọn

Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ko din ni kabiyesi meje lati ijọba ibilẹ Ikọle, nipinlẹ Ekiti, ti wọn…

Ẹ ṣaa jẹ ki Buhari da Naijiria pada si ipo to ba a nigba to de– Imaamu agba l’Abuja

Faith Adebọla Olori ẹsin Musulumi kan to n ṣaaju mọṣalaṣi Ẹsiteeti tawọn aṣofin apapọ n gbe,…

Lanre Gentry, ọkọ Mercy Aigbe tẹlẹ, ṣegbeyawo alarede

Faith Adebọla, Eko  Igbeyawo alarede mi-in ni ọkọ gbajugbaja oṣere tiata ilẹ wa nni tẹlẹ, Mercy…

Ṣẹgun ki i ṣe ṣọja, lasiko to wọṣọ ologun lati gba afurasi silẹ lọdọ ọlọpaa ni wọn mu un ni Sango

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ṣẹgun Ogundeji lo duro bii ṣọja kekere yii, ṣugbọn ki i ṣe ṣọja,…

Idajọ ododo la fẹ lori awọn tọọgi to ba ileeṣẹ burẹdi wa jẹ n’Iwo – Taawun

Florence Babaṣọla Agbarijọ ẹgbẹ awọn Musulumi kan niluu Iwo, Jama’at Taawunil Muslimeen, ti sọ pe afi…

Kayeefi! Ọkunrin yii n ba iya rẹ laṣepọ titi to fi bimọ mẹta fun un ni Kwara 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ajọ ẹsọ alaabo ṣifu difẹnsi, ẹka ti ipinlẹ Kwara, ti mu ọkunrin ọmọ…

Ara Iyabo Oko onitiata ko ya gidigidi,  o nilo iranlọwọ ọmọ Naijiria

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Lasiko ti a n kọ iroyin yii lọwọ, inu aarẹ nla ni agba…