Chibuike naa tun fipa bọmọ ọdun mẹrinla lo pọ ni Bariga Bẹẹ ni Chinedu ṣe kinni fawọn ọmọ ọga ẹ l’Aguda Faith Adebọla, Eko Baba ẹni ọdun mọkanlelọgọta kan, Eke Kanu ko ribi to maa ti ‘kinni’ ẹ bọ mọ, ọmọ bibi inu ẹ lo ba lo pọ titi tọmọ …
Read More »Ibo 1979 ku si dẹdẹ, n lawọn adigunjale ba ko girigiri ba awọn oloṣelu atijọba Ọbasanjọ (Ipari)
Ariwo, ‘yaa-fun-un yaa-fun-un’ motọ ọlọpaa lawọn eeyan to wa nile-ẹjọ giga n’Ikẹja kọkọ gbọ. Bi wọn ti gbọ ọ ni wọn dẹ eti wọn silẹ, bẹẹ lariwo fere ọlọpaa naa n sun mọ wọn si i. Oju lo n kan wọn! Ẹni ti a n gbeyawo bọ waa ba ni …
Read More »O Soju Mi Koro
Alagbara lanaa da: Oshiomhole to fẹẹ gbẹsan Nigba ti Ọlọrun ba fun ni lagbara, ko si ohun to dara bii ka mọ pe Ọlọrun lo fun ni lagbara naa, o si le gba a nigbakugba to ba fẹ. Ohun ti eyi fi dara ni pe bi a ba ti n …
Read More »Eyi ni bi aarẹ ẹgbẹ Rotaract Club ilu Iwo ṣe ku nibi to ti n gba bọọlu
Florence Babaṣọla, Osogbo Bii ala lọrọ naa ṣi n jẹ loju gbogbo awọn eeyan ilu Iwo, paapaa ju lọ, awọn ọmọ ẹgbẹ Rotaract Club, ko sẹni to gbagbọ pe ẹni ti wọn ri lai ti i pe wakati kan le ṣe bẹẹ dero ọrun alakeji. Lati ọdun kan sẹyin ni …
Read More »Wọn ṣi n wa awọn arinrinajo mẹjọ ti wọn ji gbe ni Akoko
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Titi di ba a ṣe n sọ yii lawọn agbofinro atawọn ẹṣọ alaabo lẹlẹka-jẹka ṣi n wa awọn arinrinajo kan ti wọn lawọn agbebọn ji gbe lagbegbe Akoko lọjọ Ẹti, Furaidee, ọsẹ to kọja. ALAROYE gbọ pe awọn arinrinajo ọhun ti wọn to bii mẹsan-an ni wọn n bọ lati ilu Abuja lasiko …
Read More »Okpara n lọọ ri Awolọwọ lẹwọn ni Calabar, o fẹẹ lọọ fẹjọ Akintọla ati awọn ọrẹ rẹ sun nibẹ ni
Ni Ọjọbọ, Alamisi, ọjọ kọkandinlogun, oṣu kọkanla, 1964, wọn ju Mark Ogbod sẹwọn ọdun kan niluu Owerri, nilẹ Ibo lọhun-un ti wọn n pe ni Eastern Region nigba naa. Ẹwọn oṣelu lọkunrin naa lọọ ṣe. Idi si ni pe wọn ti n wa a tipẹ, oun nikan lọmọ ile-igbimọ aṣofin …
Read More »Safu ni Iya Dele at’Anti Sikira fẹẹ gbooru ara ninu ojo ni
Ọjọ keji ni mo too le ṣalaye ohun to ṣẹlẹ nile fun Safu. Nigba ta a de ṣọọbu ni mo ṣalaye fun un. Mo ti kọkọ ro pe boya ki n ma wi fun un, mo tun tun un ro pe ko daa. Ọlọrọ abi eti didi ni, oun ko mọ …
Read More »Nwakali gba bọọlu fun kilọọbu lẹyin ọdun kan
Oluyinka Soyemi Lẹyin ọdun kan ati oṣu mẹta ti balogun ikọ agbabọọlu Golden Eaglets ilẹ Naijiria tẹlẹ, Kelechi Nwakali, ti gba bọọlu fun kilọọbu gbẹyin, o ti kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ fun Huesca, ilẹ Spain, bayii. Eyi waye l’Ọjọbọ, Tọsidee, to kọja, nibi ti kilọọbu naa ti jiya ami-ayo kan …
Read More »Ibo 1979 ku si dẹdẹ, n lawọn adigunjale ba ko girigiri ba awọn oloṣelu atijọba Ọbasanjọ (4)
Iroyin ti gbogbo ọmọ Naijiria ti n reti ni. Loootọ wọn ti gbọ oriṣiiriṣii iroyin lori ọrọ ẹjọ awọn adigunjale wọnyi, iyẹn awọn adigunjale ti wọn ja owo ileeṣẹ Boulos gba, ṣugbọn wọn ko mọ ohun ti yoo ṣẹlẹ lẹyin ti wọn ti gbọ ẹjọ naa lọtun-un losi, paapaa nigba …
Read More »Ajọ OYTMA gbẹsẹ le mọto ijọba ipinlẹ Ọyọ, wọn lo da gosiloo silẹ
Ọlawale Ajao, Ibadan “Bi gbogbo aye ba n ṣe bayii, a dun”. Eyi lọrọ ti ọpọ eeyan n sọ nigba ti ọga agba ajọ OYTMA, iyẹn, ajọ to n ri si igbokegbodo ọkọ atawọn ohun irinsẹ gbogbo ni ipinlẹ Ọyọ, Mọgaji Akin Fagbemi, fi panpẹ ọba gbe ọkan ninu awọn …
Read More »Ọwọ ọlọpaa ti tẹ mẹta ninu awọn adigunjale to yinbọn pa Afaa Jamiu l’Ondo
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọwọ ọlọpaa ti tẹ awọn afurasi mẹta kan lori Afaa kan ti wọn yinbọn pa laduugbo Yaba, niluu Ondo, laarin ọsẹ to kọja. Nnkan bii aago mẹjọ aarọ ọjọ Isẹgun,Tusidee, ọsẹ to kọja, ni wọn lawọn adigunjale mẹta kan gun ọkada wa si agbegbe ọhun pẹlu erongba …
Read More »