Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Kọmisanna fun ajọ eleto idibo, ẹka ti ipinlẹ Kwara (REC), Malam Garba Attahiru Madami, ti ni ọjọ Abamẹta, Satide, opin ọsẹ yii, ni wọn yoo bẹrẹ si i pin kaadi idibo alalopẹ fun awọn to ṣẹṣẹ forukọ silẹ nipinlẹ naa. Madami sọrọ yii lasiko to n ba …
Read More »Ọdun Itunu Aawẹ: Tinubu ko irẹsi ranṣẹ si wọn ni Kano, Nasarawa
Monisọla Saka Apo irẹsi bii ẹgbẹrun mẹta ni gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, Aṣiwaju Bọla Tinubu ko ranṣẹ sawọn eeyan ipinlẹ Nasarawa, o ni ki awọn Musulumi fi sọdun Itunu Aawe. Alakooso ẹgbẹ to n ṣe ipolongo fun Tinubu nipinlẹ naa, Yusuf Omaki, lo ṣe kokaari pinpin irẹsi ọhun niluu Lafia, …
Read More »Ẹgbẹ oṣelu PDP ṣayẹwo fawọn oludije mẹtadinlogun, wọn ja meji bọ ninu wọn
Jọkẹ Amọri Lọjọ Ẹti, Furaidee, opin ọsẹ yii, ni ẹgbẹ oṣelu PDP ṣe ayẹwo fun awọn oludije wọn bii mẹtadinlogun, ti wọn si wọgi le awọn meji ninu wọn pe wọn ko kun oju oṣuwọn lati dije dupo aarẹ lorukọ ẹgbẹ wọn. Bo tilẹ jẹ pe awọn mejeeji yii ni …
Read More »Tinubu gba fọọmu idije funpo aarẹ, Sanwo-Olu gba ti gomina
Faith Adebọla, Eko Ko si iyemeji kankan ninu ẹ mọ bayii pe gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, to tun jẹ Adari apapọ fun ẹgbẹ APC, Bọla Ahmed Tinubu, yoo dije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) lọdun to n bọ, baba naa ti gba fọọmu lọjọ Ẹti, …
Read More »Sunday fun ọmọ bibi inu ẹ loyun n’Ilẹ-Oluji, ibi to ti fẹẹ ba a ṣẹ ẹ lọwọ ti tẹ ẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn ọlọpaa ti fi pampẹ ofin gbe ọkunrin ẹni ọdun mejidinlọgbọn kan, Sunday Udoh, lori ẹsun gbigbiyanju ati sẹyun fun ọmọ to bi ninu ara rẹ to fun loyun. ALAROYE fidi rẹ mulẹ lati ẹnu Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Funmilayọ Ọdunlami, pe ọwọ tẹ Udoh lọjọ …
Read More »O ga o, pasitọ ko ibasun fun obinrin olobinrin, wọn ti wọ ọ lọ si kootu n’Ibadan
Ọlawale Ajao, Ibadan Afaimọ ni oluṣọ-aguntan kan, Ajihinrere Samson Afọlabi, ko ni i ṣe diẹ ninu iṣẹ ihinrere rẹ lọgba ẹwọn, iyẹn bo ba jẹbi ẹsun agbere ti wọn fi kan an. Ọkunrin ẹni ọdun mọkandinlogoji (39) ti wọn n pe ni Pasitọ Samson yii ni wọn lo ki obinrin …
Read More »Emi ni mo kunju oṣuwọn ju lọ lati pese idari to maa tun nnkan ṣe daadaa ni Naijiria – Ọsinbajo
Faith Adebọla “Olori to ni iriiri ni Naijiria nilo lasiko ti nnkan le koko yii. Ọdun meje ti mo ti lo nipo igbakeji aarẹ ti fun mi ni iriri lẹnu iṣejọba, emi ni mo kunju oṣuwọn ju lọ lati pese idari to maa tun nnkan ṣe daadaa.” Ọrọ yii lo …
Read More »Idi ti Jonathan ko fi le dupo aarẹ lọdun 2023- Falana
Monisọla Saka Idi ti Jonathan ko fi le dupo aarẹ lọdun 2023- Falana Agbẹjọro to tun jẹ ajafẹtọọ ọmọniyan nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Fẹmi Falana, ti sọ l’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii, pe aarẹ ilẹ wa tẹlẹ, Goodluck Ebele Jonathan, ko le jade dupo aarẹ to n bọ lọna lọdun 2023, nitori …
Read More »Iyatọ yoo ba eto ọrọ-aje ipinlẹ Ọṣun ti mo ba di gomina – Akin Ogunbiyi
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oludije funpo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Accord Party, Dokita Akin Ogunbiyi, ti sọ pe gbogbo iriri ati ọgbọn inu to sọ oun di oludaṣẹsilẹ ti ko ṣee fọwọ rọ sẹyin lorileede yii loun yoo lo lati ri i pe ipinlẹ Ọṣun di apewaawo si …
Read More »Awọn afiniṣowo pa agunbanirọ niluu Abuja, wọn yọ gbogbo ẹya ara rẹ lọ
Monisọla Saka Ofo nla gbaa leyi jẹ, ọmọbinrin agunbanirọ to sọnu, Stephanie Ṣe-Ember Terungwa, pẹlu nọmba idanimọ FC/21B/5807, ni wọn ti pada ri, ṣugbọn wọn ko ri i laaye, oku rẹ ni wọn ri, bẹẹ ni ẹya ara rẹ ko pe mọ, wọn ti yọ oju ara rẹ atawọn nnkan …
Read More »O ma ṣe o, ọkunrin kan padanu ẹmi rẹ lasiko to fẹẹ yọ foonu rẹ to ja bọ sinu ṣalanga
Monisọla Saka Ọkunrin ẹni ogoji ọdun kan, Mu’azu Garba, ti ku sinu sọkawee ni Jigirya, nijọba ibilẹ Nassarawa, nipinlẹ Kano, lakooko to n gbiyanju lati yọ foonu rẹ to ja bọ nigba to n yagbẹ lọwọ. Alukoro ileeṣẹ panapana nipinlẹ naa, Alhaji Saminu Abdullahi, lo fọrọ ọhun lede l’Ọjọbọ, Tọsidee, …
Read More »